Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria

Oríṣun àwòrán, @Chikwe_I
Arun Coronavirus tun ti mu ẹmi eeyan mẹjọ miran lọ ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ NCDC fi lede loj opo Twitter rẹ lalẹ ọjọ Aiku, eeyan 1,024 tuntun miran lo tun fara kasa arun ọhun bayii.
Esi yii ti sọ apapọ awon to ti ko arun naa ni Naijiria lapapọ di 100,087, awọn 80,030 ti ri iwosan nigba ti awọn 1,358 ti dero ọrun.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa kaakiri Naijiria ṣe lọ ree:
Lagos-653
Plateau-63
Benue-48
Zamfara-45
FCT-42
Rivers-27
Ondo-26
Adamawa-26
Kaduna-22
Edo-18
Ogun-16
Imo-12
Kano-9
Yobe-6
Ekiti-5
Jigawa-4
Osun-2
Lọ́jọ́ Àbámẹ́ta èèyàn mẹ́jọ mìíràn ló pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ ààrùn COVID-19 ní Nàìjíria

Oríṣun àwòrán, Twitter/ncdc
Nilẹ ọjọ Abamẹta to ṣu ni Naijiria, iye eeyan to dagbere faye gba tọwọ aarun Covid-19 ni Naijiria tun ti lekun si.
Iroyin lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria NCDC sọ pe eeyan mẹjọ lo ku ti awọn eeyan ẹgbẹjọ din mẹẹdogun si tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun naa.
Ipinlẹ Eko lo ṣi le tenete nipinlẹ ti ọwọja aarun yi ti peleke ti Bauchi si ni iye eeyan to kere julọ.
Ni apapọ awọn to ti ni aarun naa, ajọ naa ni wọn jẹ 99,063.
Eeyan 79,417 lo ti pada sile lẹyin tara wọn ya ti apapọ awọn to ti ku si jẹ 1,350.
1585 new cases of #COVID19Nigeria;
Lagos-573
FCT-182
Plateau-162
Gombe-81
Oyo-75
Rivers-68
Sokoto-58
Ondo-55
Ogun-42
Nasarawa-40
Akwa Ibom-36
Edo-31
Kaduna-27
Anambra-22
Delta-19
Kano-17
Osun-17
Ebonyi-16
Katsina-14
Niger-14
Bayelsa-9
EKiti-8
Borno-7
Jigawa-5
Abia-4
Bauchi-3
COVID-19 pa èèyàn mọ́kànlá láàrín ọjọ́ méjì, ènìyàn 1565 míràn tún ko lọ́jọ́ kan ṣoṣo ní Nàìjíria
Eeyan mọkanla ni ajakalẹ aarun COVID-19 ti ran lọ sọrun lorilede Naijiria laarin ọjọ meji pere ni Naijiria bayii.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ lalẹ Ọjọbọ, eeyan mẹfa miran lo kun iye awọn eeyan to ku nipaṣẹ aarun naa lẹyin ti o ti kọkọ gbee sita pẹlu ni Ọjọru pe eeyan marun miran ku.
Gẹgẹ bi awọn onwoye ṣe n woo, eyi ko fẹẹ ṣẹyin ọwọja ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19, eyi to ti gbagboro kan bayii.
Ẹwẹ, eeyan Ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta o le marundinlaadọrin, 1565 lo tun kun awọn to ko aarun naa naa bayii.
Eyi si sọ iye awọn to ti lugbadi aarun naa bayii di ẹgbẹrun marundinlọgọrun ati ẹẹdẹgbẹrun o le mẹrinlelọgbọn, (95, 934).
Iye awọn to ti ku lapapọ ti di ẹgbẹrun kan ati ọọdunrun o le ọgbọn, (1330)
Lagos-807
FCT-236
Kaduna-79
Oyo-57
Plateau-47
Rivers-37
Katsina-35
Edo-30
Sokoto-30
Delta-26
Kebbi-23
Ondo-20
Enugu-18
Abia-17
Ogun-17
Benue-16
Bayelsa-15
Bauchi-14
Niger-13
Kano-10
Borno-6
Imo-5
Ekiti-4
Osun-2
Jigawa-1
COVID-19 pa èèyàn márùn ún, ènìyàn 1664 míràn tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria

Eeyan marun ni ajakalẹ arun COVID-19 tun ti pa bayii lorilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC sọ loju opo twitter rẹ ẹgbẹrun kan ati ọtalelẹgbẹta o le mẹrin 1664 lawọ ti aarun naa tun ṣẹṣẹ mu bayii
o fi kun pe, eeyan ọrinleldunrun ati mẹj (388) ni ipinl Eko, ọtalelugb o le ẹykan (261) ni Kaduna, mẹtadinlaadọrun (87) ati ogun (20) lo ti ri iwosan bayii.
Lagos-642
FCT-407
Plateau-160
Kaduna-83
Rivers-62
Adamawa-47
Nasarawa-38
Abia-29
Edo-28
Anambra-27
Niger-24
Ogun-24
Imo-15
Oyo-14
Kano-12
Osun-12
Borno-9
Delta-7
Enugu-7
Bauchi-5
Ekiti-5
Sokoto-5
Jigawa-2
Ènìyàn 1354 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe Ẹgbẹrun kan o le ọọdunrun ati mẹrinlalaadọta eeyan (1354) miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe ẹgbẹrun mẹrindinlọgọrin o le mẹrindinni irinwo, (76, 396) eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Lagos-712
FCT-145
Plateau-117
Kwara-81
Kaduna-54
Sokoto-39
Oyo-38
Rivers-37
Gombe-21
Enugu-20
Akwa Ibom-16
Bauchi-14
Delta-14
Ebonyi-13
Anambra-9
Taraba-8
Edo-8
Kano-3
Osun-2
Ekiti-2
Ogun-1
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 1
Ènìyàn 576 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 576 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 89,163 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 2
Ẹ̀ funra, ó lé ní 4,000 ènìyàn tó ń gba ìtọ́jú nílé l'Eko nítórí àrún Coronavirus
Ijọba ipinlẹ Eko ti ni o le ni ẹgbrun mẹrin( 4,176 )eniyan to n gba itọju arun Coronavirus ni ile, lẹyin ti wọn ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus.

Oríṣun àwòrán, Twitter
Kọmisọnna fun eto ilẹra nipìnlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi lo sọ bẹẹ loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Bakan naa lo fikun pe o le ni eniyan marundinlọgọfa lo wa ni ahamọ ni ile iwosan to n tọju arun Coronavirus.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 3
Kọmiṣọnna fun eto ilera naa ni awọn ijọba ibilẹ bii marun un ni Eti-Osa, Ajeromi, Surulere, Amuwo- Odofin ati Mushin ni awn eniyan to lugbadi arun naa ti pọ.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 4
Abayomi ni ipinlẹ Eko lo ti ṣe ayẹwo arun Coronavirus julọ lorilẹede Naijiria pẹlu eniyan 236,212 to ti ṣe ayẹwo ọhun ni ipinlẹ Eko.
O ti fẹrẹ to ọsẹ kan bayii ti iye eniyan to n lugbadi arun Coronavirus ti n le ni 1000 ní ojoojumọ.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 5
Ni Ọjọ Ẹ̀ti, eniyan to le ni ẹgbẹrun (1,074) lo tun ṣẹṣẹ lugbadi arun ohun kaakiri orilẹede Naijiria.
Nínú ọdún tuntun, ènìyàn 1,031 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria

Oríṣun àwòrán, NCDC
Bi a ti ṣe n wọ inu ọdun tuntun loni, Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,031 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 87,510 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 6
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,016 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 86,576 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 7
Ènìyàn 749 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria

Oríṣun àwòrán, Ncdc
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 749 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 85,560 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 8
Ènìyàn 397 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 397 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 84,414 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 9
Ènìyàn 838 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria

Oríṣun àwòrán, NCDC
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 838 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 84,414 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 10
Ènìyàn 829 ló ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria nínú èsì àyẹ̀wò tó jáde lọ́jọ́ sátidé
Èsì àyẹ̀wò Coronavirus tuntun to jáde lọ́jọ́ satide lórílẹ̀-èdè Naìjíríà fi han pé ènìyàn ẹgbẹ̀rin àti mọ́kandinlọ́gbọ̀n tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ni Nàìjíríà.

Oríṣun àwòrán, NCDC
Gẹ́gẹ́ bi àtẹ́jáde àjọ tó n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ṣe fi síta lójú òpó twitter rẹ̀, ìpínlẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko, Abuja àti Kaduna lo lé ténté tábìlì.
Nínú àtẹ̀jáde ọ̀hún, ìpínlẹ̀ Eko ni 296 nígbà ti Abuja ni 291, Kadujna ni 79 nígbpa ti Rivers ni 40.
Kano 35 Nasarawa 25, Bauchi 19, Benue 8, nígbà tí Borno, Edo, Oyo àti Sokoto ni 7, Ogun ni 2
Ìpínlẹ̀ mẹ́ẹ̀dógun ni àjọ NDCD kọ sojú òpó wọ́n pé wọ́n ti rí àwọn tó ni ààrùn yìí wọ́n ko fi iye ènìyàn tó ni ààrun náà ní Jigawa soju òpó wọ́n .

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ní báyìí iyed ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn cororvirus ni Nàìjíríà tí lé ni mẹ́tàlélọ́gọ́rin (83,576) nígbà ti àwọn to ti rí ìwòsàn gbà ti lẹ́ ni àádọ́rin (70,495). Ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún kan (1,247) ló ti ba corovirus rin lọ́dun 2020.
Ènìyàn 712 ló ní ààrùn Covid-19 ni Nàìjíria nínú èsì àyẹ̀wò tó jáde lọ́jọ́ ọdún kérésì

Oríṣun àwòrán, NCDC
Èsì àyẹ̀wò Coronavirus to jáde lọ́jọ́ kérésìmesì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà fi hàn pé, ènìyàn ẹ̀ẹ́dẹ́ẹ̀rin àti méjìlá ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid -19 ni Nàìjíríà.
Gẹ́gẹ́ bi àtẹ́jáde àjọ tó n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ṣe fi síta lójú òpó twitter rẹ̀, ìpínlẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko, Abuja àti Kaduna lo l;e ténté tábìlì.
Nínú àtẹ̀jáde ọ̀hún, ìpínlẹ̀ Eko ni 338 nígbà ti Abuja ni 77, Kwara náà tun ni 39 nígbà ti Katsina ni 35.
Bauchi ni 33 nígbà tí Plateau ni 22, Ogun ni 18, Akwa-Ibom si ni 16, Delta ni 13, sùgbọ́n Kaduna àti Osun jọ ni 12.
Yobe ni 1, Sokoto ni 10, Kebbi ni 8 nígbà tí Enugu ni 6, Edo ní 5 nígbà ti Ondo ni 3 Niger ni 2 sùgbọ́n Kano àti Oyo ni ẹyọ kan péré.
Gbogbo àpapọ̀ àwọn tó ti lùgbàdi ààrùn Coronavirus nni Nàìjíríà ti di ẹgbẹ̀rún méjìlélélọ́gọ́rin ọ le díẹ̀ (82,747) tí àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́rín ó lé díẹ̀ (70239) sì ti rí ìtọ́jú gbà.

Oríṣun àwòrán, NCDC
Àwọn tó bọ́ lọ́wọ́ Coronavirus ni ìpínlẹ̀ Eko àti Kaduna lé díẹ̀ ni ọ̀ọ́dúnrún
O lé ni ẹgbẹ̀rún ènìyǹ to ti bá ààrùn Covid-19 rìn lọ́dún yìí.

Oríṣun àwòrán, NCDC
Èèyàn 1,041 tuntun míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara kásá Coronavirus ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Esi ayẹwo Coronavirus lati ipinlẹ mejilelogun at Abuja ti ajọ NCDC ṣẹṣẹ fi sita ti fi han pe, eeyan 1,041 tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko lo le waju, ti Abuja, Kaduna atawọn ipinlẹ to ku n sare tete tẹle wọn lẹyin.
Lagos-316
FCT-210
Kaduna-83
Plateau-70
Gombe-56
Oyo-56
Katsina-47
Nasarawa-35
Kano-33
Ogun-21
Rivers-17
Niger-14
Imo-14
Delta-12
Kwara-12
Edo-12
Benue-9
Anambra-8
Taraba-4
Ekiti-4
Ebonyi-6
Bayelsa-1
Sokoto-1
Èèyàn márùn ún kú, 1,133 tuntun míràn tún ní Coronavirus ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC
Ènìyàn 1,133 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹ́gẹ́ bi àjọ tó n mójú tó ń àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà, NCDC, se sọ lójú òpó twitter rẹ̀, ipínlẹ̀ mejidinlogun ni awọn eeyan naa ti wa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 80,922, eyan 69,274ti ri iwosan, 1,236 si ti ku.
Eko -397
FCT-357
Kaduna-81
Plateau-63
Katsina-46
Sokoto-32
Oyo-28
Ogun-21
Kano-19
Rivers-18
Osun-13
Edo-12
Niger-12
Bayelsa-11
Borno-11
Bauchi-8
Jigawa-2
Ondo-2
Èèyàn mẹ́rin kú, 999 tuntun míràn tún lùgbàdì Covid-19 ní Naijiria

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 999 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 79,789 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
68,879 ti gba iwosan nigba ti awọn 1,231 ti ba arun naa lọ.
FCT-416
Eko -324
Kaduna-68
Plateau-42
Kwara-32
Kano-24
Gombe-14
Sokoto-12
Yobe-12
Akwa Ibom-11
Bayelsa-10
Rivers-7
Bauchi-7
Ogun-6
Oyo-5
Edo-4
Taraba-4
Jigawa-1
Èèyàn mẹ́fà kú, 356 tuntun míràn tún fara kásá Coronavirus ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede esi ayẹwo ẹrindinlọgọtalelọọdunrun eeyan to tun ṣẹṣẹ lugbadi Coronavirus ni Naijiria.
Ilu Abuja ni awọn to ni i pọ si ju pẹlu eeyan mọkandinlọgọrin, nigba ti eeyan mọ́kàndínlọ́gọ́ta ni ni ipinlẹ Eko, ti Kaduna atawọn ipinlẹ mejila miran si n tẹle lẹyin.
Bi awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ree:
FCT-79
Lagos-59
Kaduna-56
Katsina-37
Nasarawa-30
Kano-25
Edo-18
Gombe-14
Kebbi-12
Akwa Ibom-7
Rivers-7
Sokoto-7
Abia-3
Ogun-1
Cross River -1
Èèyàn mẹ́ta jẹ́ Ọlọrun nípè, 501 míràn tún fara kásá Coronavirus ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ NCDC tun ti kede esi ayẹwo ọkanlelẹẹdẹgbẹta eeyan to tun ṣẹṣẹ ni Coronavirus ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko ni awọn to ni i pọ si ju pẹlu eeyan mọkanlenigba, nigba ti eeyan méjìléláàdọ́fà ni ni Abuja, ti Kaduna atawọn ipinlẹ mejila miran si n tẹle lẹyin.
Biu awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ree:
Plateau-24
Katsina-21
Kano-16
Yobe-14
Ondo-10
Ogun-9
Edo-7
Bayelsa-5
Rivers-4
Borno-4
Osun-2
Ekiti-2
Èèyàn mẹ́fà kú, 920 tuntun míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Naijiria

Esi ayẹwo Coronavirus lati ipinlẹ mejidinlogun ti ajọ NCDC kede loru ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2020, fihan pe, eeyan ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárun le ogun tuntun miran lo ṣẹṣẹ ni aarun naa ni Naijiria.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria bayii ti pe 77,933, eeyan 67,784 ti ri iwosan, nigab ti awọn 1,218 ti dagbere faye.
Bi awọn ipinlẹ naa ṣe lọ ree:
Eko-308
FCT-207
Kaduna-179
Plateau-46
Niger-43
Adamawa-26
Sokoto-18
Rivers-16
Yobe-15
Enugu-13
Kano-13
Ogun-12
Delta-10
Edo-5
Osun-3
Oyo-3
Anambra-2
Ekiti-1
Èèyàn 806 míràn tún lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Eeyan ẹgbẹrin lẹ mẹfa lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n moju to n ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ lọjọ Ẹti, ipinlẹ mẹrindinlọgbọn pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun naa ti ṣẹyọ pẹlu arun naa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria bayii ti pe 77,013, eeyan 67,484 ti ri iwosan, nigab ti awọn 1,212 ti dagbere faye.
Lagos-287
FCT-255
Kaduna-36
Akwa Ibom-29
Katsina-25
Rivers-25
Kwara-21
Bauchi-19
Kano-15
Ondo-14
Plateau-13
Yobe-12
Nasarawa-11
Ebonyi-9
Gombe-8
Abia-7
Delta-4
Imo-4
Osun-3
Anambra-2
Borno-2
Cross River-1
Edo-1
Ekiti-1
Jigawa-1
Ogun-1
Èèyàn tó lè ní ẹ̀gbẹ̀rún kàn,1,145 lùgbàdì àrùn Covid-19 ní ìgbà àkọ̀kọ̀ ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, @NCDC
Nigba akọkọ ti arun Covid-19 ti bẹrẹ, iye awọn eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria ti kọja ẹgbẹrun kan lojumọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, oke tente ni iye awọn to lugbadi arun naa n lọ bi ọdun Keresimesi ti se n kan lẹkun dẹdẹ.
Loju opo ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) niṣe ni wọn kede pe eeyan ẹgbẹrun kan ati marundinlaadọjọ,1,145 tuntun miran ti lugbadi arun naa lọjọbọ.
Ninu atupalẹ iye awọn to ko arun yi, ipinlẹ Eko lewaju pẹlu eeyan 459 ti Abuja si tẹle pẹlu 145.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 11
Kaduna ati Plateau naa ko gbẹhin bi wọn ti 'ṣe ni eeyab 138 ati 80 eeyan to ko arun naa.
Lọwọlọwọ apapọ iye eeyan to ti ba arun naa lọ ti pe 1201 ti apapọ awọn to lugbadi r ni Naijiria si jẹ 76207 ti ara awọn 67110 si ti ya.
Ẹwẹ awọn ijọba ipinlẹ kọọkan bi Eko ti kede ọjọ ti gbogbo akẹkọọ ile ẹkọ ijọba ati aladani gbọdọ pari eto ẹkọ saa kini ọdun 2020/2021.
Loju opo Twitter wọn ti ikede yi wa, wọn ni kawọn obi ri wi pe wọn tẹle ilana idaabo Covid-19 ṣaaju ki awọn akẹkọọ to pada sile ẹkọ lọjọ Kẹrin oṣu Kini 2021.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 12
Èèyàn 930 míràn tún lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Naijiria
Eniyan ẹẹdẹgbẹrun o le ọgbọn lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ l'Ọjọru, ipinlẹ mọkanlelogun pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun tun ti ṣẹyọ pẹlu arun naa lọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2020.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 75,062, eeyan 66,775 ti ri iwosan, 1, 200 si ti ku.
Lagos-279
FCT-179
Plateau-62
Kaduna-54
Kano-52
Katsina-52
Imo-42
Jigawa-42
Rivers-38
Kwara-30
Nasarawa-19
Yobe-15
Ogun-13
Borno-10
Oyo-9
Niger-9
Ebonyi-6
Bauchi-6
Edo-5
Taraba-4
Sokoto-2
Cross River-2
Èèyàn mẹ́ta míràn kú, olú ìlú Nàìjíríà, Eko, Kaduna léwájú ìṣẹ̀lẹ̀ Covid-19 ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Ncdc
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkandinlogun ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karundinlogun oṣu kejila ọdun 2020 fihan pe, eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din meji, 758 lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Bakan naa lo fi kun un pe eeyan mẹta larun naa tun ti ran lọ sọrun, eyi si ti mu iye awn to ti ko arun naa di ẹgbẹfa, 1200.
FCT-305
Lagos-152
Kaduna-103
Bauchi-44
Gombe-35
Plateau-31
Rivers-17
Sokoto-15
Kwara-13
Kano-9
Ebonyi-8
Ogun-5
Osun-5
Oyo-4
Edo-4
Anambra-4
Bayelsa-2
Ekiti-1
Taraba-1
Apapọ awọn to ti ni -74,132
Awọn to ti ri iwosan - 66,494
Awọn to ti ku - 1,200
Ènìyàn mẹ́ta kú, 418 míràn tun ṣubú sínú àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, Twitter/ncdc
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọru, ọjọ keji, oṣu Kejila dun 2020, (02-12-2020), fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lagos-113
FCT-86
Abia-47
Kaduna-39
Rivers-27
Katsina-22
Benue-14
Oyo-13
Kano-12
Enugu-8
Edo-7
Imo-7
Bauchi-6
Ebonyi-6
Ogun-6
Ondo-4
Nasarawa-1
Ẹgbẹrun mẹtalelaadọrin o le marundinlọgọsan (73,175) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹrindinlaadọrin o le aadọrun (66, 090) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati igba o din mẹta (1197) eeyan.
Covid-19 tún ti ran èèyàn 796 míràn ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, Ncdc
Eniyàa mẹrindinlẹgbẹrin lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n moju to n ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ lọja Ẹti, ipinlẹ marundinlogun pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun tun ti ṣẹyọ pẹlu arun naa lọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 72,140, eeyan 65,722 ti ri iwosan, 1,190 si ti ku.
FCT-258
Lagos-248
Kaduna-117
Katsina-52
Ogun-27
Kwara-23
Gombe-22
Adamawa-17
Plateau-15
Kano-6
Rivers-2
Ondo-2
Ekiti-2
Nasarawa-2
Sokoto-2
Taraba-1

Eeyan 675 tun ni COVID-19 ni Naijiria
Eeyan ẹgbẹta ati marundinlọgọrin ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kejila dun 2020 fihan pe o tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 13
Bakan naa ni Covid-19 hun tun ṣekupa eeyan mẹfa.
Èèyàn 590 ló tún ti ní covid-19 ní Naijiria
Ajọ NCDC ti kede eeyan ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹwa to tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Esi ayẹwo ọhun to wa lati ipinlẹ mẹrindinlogun, ati ilu Abuja, lo ti i pọ ju lati oṣu diẹ sẹyin.
Lagos-219
FCT-168
Kaduna-52
Kwara-19
Kano-15
Rivers-15
Sokoto-10
Enugu-9
Gombe-8
Plateau-7
Osun-7
Anambra-5
Oyo-5
Jigawa-4
Ogun-4
Bauchi-2
Edo-1
Akojọpọ awọn to ti ni aarun naa ni 70,195. Awọn 65,110 ti ri iwosan. O si ti ṣekupa 1,182.
Èèyàn 390 ló tún ti ní covid-19 ní Naijiria
Eeyan irinwo din mẹwa lo tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Esi ayẹwo ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, fi sita ni ọjọ Aje fihan pe ipinlẹ mọkandinlogun, ati ilu Abuja ni awọn esi naa ti wa.
FCT-89
Gombe-89
Kaduna-62
Lagos-35
Kwara-15
Borno-13
Nasarawa-10
Rivers-10
Bauchi-8
Ogun-8
Osun-7
Bayelsa-7
Kano-7
Edo-6
Taraba-6
Ekiti-5
Katsina-5
Akwa Ibom-4
Delta-3
Sokoto-1
Èèyàn 318 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà, sùgbọ́n ara ará ilú 60 ló dá
Àjọ tó n gbógun ti ìtàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) ti kéde pé ènìyàn 318 ló tí ni ààrùn coronavirus ní Nàìjíríà.
Nínú àtẹ̀jáde ojoojúmọ́ ilé iṣẹ́ náà lójú òpó twitter rẹ̀ ló lo ti salaye pé, ìpínlẹ̀ méjìlá ni ọwọ́jà ààrùn náà dé dúró ní Nàìjíríà fún tí ọjọ́ kẹrin osù kejìlá ọdún 2020.
Nínú àtẹ́jáde náà, ìpínlẹ̀ Eko ló ń léwájú pẹ̀lú ènìyàn 104, ìpínlẹ̀ Kaduna tẹ̀lée pẹ̀lú 59, Abuja 50 nígbà ti Rivers 17 Ogun 16.
Bákan náà Kano-14, Nasarawa-14, Akwa Ibom-10, Katsina-10, ńigbà tí Edo-7.
Oyo àti Sokoto ni 5, Plateau ni 4 tí Taraba si ni 3
Àjọ tọ n gbógun ti ìtànkálẹ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ti kéde pé ènìyàn ọ̀ọ̀dúnrun àti mẹ́w['a ló tun ṣẹ̀sẹ̀ lùgbàdì ààrùn coronavirus lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Nínú àtẹ̀jáde ojoojúmọ́ ilé iṣẹ́ náà lójú òpó Twitter rẹ̀ ló lo ti salaye pé, ìpínlẹ̀ méjìlá ni ọwọ́jà ààrùn náà dé dúró ní Nàìjíríà fún tí ọjọ́ kẹrin osù kejìlá ọdún 2020.
Nínú àtẹ́jáde rẹ̀, òlúùlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Abuja ló ń léwájú pẹ̀lú ènìyàn 128, ìpínlẹ̀ Eko tẹ̀lée pẹ̀lú 86, Kaduna ni 26 nígbà ti Katsina náà ni 20
Àwọn ìpińlẹ̀ tó kù ni Rivers 19, Oyo 7, Benue, Edo, jigawa àti Ogun ní 5 tí Bayelsa ati Kano sì ni 2.
Ní báyìí ènìyàn tó dín díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rùn lọ́nà ààdọ́rin ló ti lùgbàdì ààrun Covid-19 ní Nàìjíríà, nígbà ti ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnleọgọ́ta ti gba iwòsàn
Bákan náà ní ènìyin tó lé ni ẹgbẹ̀run kan ni ikú ti pa.
Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Kaduna ní èèyàn 37 nínú àwọn 122 tí Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọru, ọjọ keji, oṣu Kejila dun 2020, (02-12-2020), fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Kaduna-37
Lagos-29
Plateau-25
Ekiti-9
Rivers-5
Ogun-5
Edo-4
Kwara-4
Bayelsa-2
Bauchi-1
Kano-1
Ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọtalelẹẹdẹgbẹrun (67,960) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta ati ojilelẹgbrin o din ẹykan (63, 839) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan
O dabi ẹni pe coronavirus tun ti n gbilẹ si diẹ diẹ lorilẹede Naijiria. Eeyan eeyan ọrinlelugba o le ẹyọkan lo ko aarun naa lọjọ Iṣẹgun.
Mẹtalelọgọfa ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko eyi si lo pọju ninu gbogbo ipinlẹ lọjọ Iṣẹgun.
Olu ilu ilẹ Naijiria, FCT lo ṣe ipo keji nibi ti eeyan mẹrinlelọgọta ti lugbadi aarun ọhun.
Eeyan mejidinlogoji lo laarun naa lati Kaduna, marundinlogun lati Imo, mọkanla lati ipinlẹ Rivers nigba ti eeyan mẹjọ ni ni Plateau.
Eeyan marun un lo lugbadi aarun naa lati Ogun nigba ti eeyan mẹrin-mẹrin ni aarun covid-19 lati Bayelsa ati Kwara.
Eeyan mẹta-mẹta lo nii lati Bauchi ati Edo ti eeyan meji si ko aarun naa ni Kano
Eeyan kan ṣoṣo layẹwo fihan pe o ni aarun naa ni ipinlẹ Ọṣun.
Èèyàn 145 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mẹjọ ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lagos-49
FCT-34
Kaduna-34
Plateau-11
Oyo-7
Bayelsa-5
Taraba-4
Sokoto-1
Ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọtalelẹdẹgbẹta o din mẹta (67,557) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta ati ọrinlelugba ati meji (63,282) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Èèyàn 82 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ Aiku. ọjọ kọ̀kandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan mejilelọgọrin tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lagos-48
Rivers-8
Kwara-6
Yobe-6
Katsina-5
FCT-3
Nasarawa-2
Plateau-1
Ogun-1
Kano-1
Osun-1
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le irinwo ati mejila (67,412) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta o le marundinlgọta (63,055) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Èèyàn 110 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà
Eeyan aadọfa lo tun kun iye awọn eeyan to laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe fi sita, eeyan mẹrindinlọgbọn lo tun ko arun naa ni ipinlẹ Eko, mẹtalelogun fara kaasa rẹ ni olu ilu orilẹede yii, ogun eeyan lati ipinlẹ Kaduna ti mọkanla si wa lati ipinlẹ Katsina.
Ẹwẹ, ni ipinlẹ Ogun, eeyan meje lo tun ko aarun naa bayii, mẹfa lati ipinlẹ Ekiti, marun un lati ipinlẹ Plateau, mẹrin lati ipinlẹ Rivers, Kano ni mẹta, Nasarawa ni mẹta ti Niger si ni meji.
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọọdunrun ati ọgbọn (67,330) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni ibẹrẹ ọdun 2020. Ẹgbẹrun mejilelọgọta o le ẹgbẹrin ati mọkandinlogun (62,819) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mọkanlelaadọjọ (1171) eeyan.
Èèyàn 246 ló ní COVID-19 lọ́jọ́ Ẹti ní Nàìjíríà
Alekun eeyan ojilelugba ati mẹfa lo tun ko arun COVID-19 gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe gbe e jade lọjọ Ẹti.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa fi sita loju opo ẹyẹnkọrin Twitter rẹ, ipinlẹ Eko lo lewaju pẹlu eeyan mọkanlelogoji ti olu ilu ilẹẹwa naa si gba tẹlẹ pẹlu eeyan mẹtalelaadọrin.
Ipinlẹ Plateau-39, Kaduna-25, Ogun-13, Bauchi-5, Rivers-4 Ekiti-2, Taraba-2 ati kano-2 pẹlu ko gbẹyin.
Nibayii iye awọn to ti lugbadi arun naa lorilẹede Naijiria ti le lẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin.
Ìpínlẹ̀ Kaduna ní èèyàn 74 nínú àwọn 169 tí Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mejila ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọbọ. ọjọ krindinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan mọkandinlaadọsan tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Kaduna-74
FCT-42
Lagos-17
Kano-8
Ogun-6
Oyo-6
Rivers-6
Ekiti-3
Bauchi-3
Katsina-2
Delta-1
Ondo-1
Apapọ awọn to ti ni - 66,974
Awọn to ti ri iwosan - 62,585
Awọn to ti ku - 1,169
Èèyàn 198 ni Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria ní 25/11/2020
Eeyan igba din meji lo tun ti ni aarun Covid-19 ni Naijiria.
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe jade, lati ipinlẹ mejila, ati ilu Abuja.
Bi awọn esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:
FCT -53
Lagos-48
Ogun-40
Akwa Ibom-20
Bauchi-9
Plateau-8
Kaduna-5
Kano-4
Benue-3
Jigawa-3
Nasarawa-3
Edo-1
Kwara-1
Àjàkálẹ̀ Coronavirus ran èèyàn 168 ní Naijiria, ó pa ẹnì kan ní 24/11/2020
Ajọ NCDC tun ti kede esi ayẹwo eeyan mejidinlaadọsan. to tun ṣẹṣẹ ni coronavirus.
Ilu Abuja ni awọn to ni i pọ si, pẹlu eeyan mọkanlelọgọta, nigba ti eeyan ọgọta ni nipinlẹ Eko.
Awọn ipinlẹ to ku ni
Kaduna-27
Oyo-12
Rivers-6
Katsina-5
Ogun-3
Kwara-2
Edo-1
Kano-1
Apapọ awọn to ti ni jẹ 66,607, ti 62,311 si ti ri iwosan. Amọ, o ti ṣekupa eeyan 1,169.
Èèyàn 56 ni Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria ní 23/11/2020
Itankalẹ coronavirus ni Naijiria ja walẹ lọjọ Aje, pẹlu bi esi ayẹwo ṣe fihan pe eeyan mẹrindinlọgọta pere lo ṣẹṣẹ ràn.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe, eeyan kan kú.
Kaduna-18
FCT-17
Lagos-6
Plateau-5
Kano-3
Kwara-2
Yobe-2
Ekiti-1
Niger-1
Rivers-1
Apapọ awọn to ti ni jẹ 66,439, ti 62,241 si ti ri iwosan. Amọ, o ti ṣekupa eeyan 1,168.
Covid-19 tún ran èèyàn 56 ní Naijiria, ó ṣekú pa ẹni kan ní 22/11/2020
Eeyan marundinlaadọjọ ni esi ayẹwo fihan pe o tun ti ni aarun Covid-19 ni Naijiria.
Eyi jẹyọ ninu esi ti ajọ NCDC fi sita ni alẹ ọjọ Aiku.
Lagos-60
Katsina-37
Kaduna-35
FCT-6
Ogun-4
Edo-3
Kwara-3
Rivers-2
Kano-2
Jigawa-1
Oyo-1
Taraba-1
Èèyàn 246 tún kó Covid-19 ní Nàìjíríà ní 21/11/2020
Esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC fi sita lọjọ Abamẹta fihan pe eeyan ojilerugba ati mẹfa, 246, eeyan lo ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Lagos-66
Plateau-63
FCT-48
Kaduna-21
Bayelsa-19
Rivers-12
Niger-9
Ogun-4
Ekiti-2
Bauchi-1
Osun-1
Eyi tumọ si pe awọn to ti ni Covid-19 ni Naijiria ti pe 66,228, nigba ti eeyan 61,884, ti ri iwosan, awọn 1,166 si ti ku.
Ìpínlẹ̀ Eko, Ọyọ ló lékè nínú àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria
Apapọ awọn to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti pe 65,457 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 152 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Eko-61
Oyo-39
FCT-13
Yobe-10
Bauchi-6
Kaduna-5
Kano-4
Kwara-4
Plateau-4
Edo-2
Ogun-2
Rivers-2
Èèyàn 157 míràn ló tún lùgbàdì Coronavirus ní Nàìjíríà
Apapọ awọn to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti pe 65,148 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 157 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Eko-97
Oyo-37
Kaduna -9
Bayelsa-3
Edo-3
Ekiti-3
Ondo-2
Osun-2
Plateau-1
Ìpínlẹ̀ Eko ní èèyàn 136 nínú èèyàn 152 lápapọ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà
Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 65,148 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 152 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Eko-136
Kano-4
Niger-3
Ekiti-2
Kaduna-2
Ogun-2
Taraba-2
FCT-1
Èèyàn 112 míràn ló tún lùgbàdìi Coronavirus ní Nàìjíríà
Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 64,996 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 112 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
FCT-27
Oyo-27
Bayelsa-9
Rivers-9
Delta-7
Edo-5
Kaduna-5
Ogun-5
Anambra-3
Katsina-3
Ondo-3
Osun-3
Plateau-3
Niger-2
Kano-1
Àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19 búrẹ́kẹ́ si ní Nàìjíríà, èèyàn 212 ló tún ràn
Itankalẹ Covid-19 ni Naijiria tun ṣe bi ẹni l'agbara si, pẹlu esi ayẹwo to fihan pe eeyan 212 tun ti ni, l'Ọjọbọ.
Esi naa ti ajọ NCDC fi sori ayelujara Twitter rẹ fihan pe
Lagos-71
Imo-26
Plateau-26
FCT-19
Ondo-17
Kaduna-14
Rivers-9
Oyo-9
Katsina-6
Osun-4
Bauchi-2
Ekiti-2-
Nasarawa-2
Ogun-2
Kano-1
Kwara-1
Taraba-1
Coronavirus ran èèyàn 180 míì ní Nàìjíríà ní 11/11/2020
Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 64,515 bayii. eyi waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo ọgọsan eeyan to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Lagos-74
Oyo-41
FCT-19
Kaduna-19
Bauchi-12
Ogun-7
Rivers-4
Cross River-2
Edo-2
Èèyàn 152 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ coronavirus ní Nàìjíríà
Esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, fi sita lọjọ Iṣẹgun fihan pe eeyan mejilelaadọjọ lo tun ti ni coronavirus.
Ipinlẹ Eko lo wa ni ipo kinni pẹlu 93, FCT si wa ni ipo keji pẹlu 21.
Awọn ipinlẹ to ku ni:
Oyo-15
Rivers-11
Bauchi-7
Kwara-2
Bayelsa-1
Edo-1
Plateau-1
Èèyàn 94 míràn ló ni coronavirus ní Nàìjíríà ní 09/11/2020
Bayii ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC gbe sita lọjọ Aje, ọjọ kẹsan-an, oṣu Kọkanla, ṣe lọ.
Lagos-50
FCT-24
Kwara-9
Edo-4
Kaduna-3
Ondo-2
Plateau-2
Apapọ awọn to ti ni ti pe 64,184, lara si ni 60,069 ti ri iwosan. Awọn 1,158 si ti ku.
Èèyàn 300 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Aiku
Ajakalẹ aarun coronavirus tun ti gbera soke si ni orilẹ-ede Naijiria, pẹlu bo tun ṣe ran ọọdunrun (300) eeyan mii.
Ninu esi ayẹwo to fi sita lọjọ Aiku, ajọ NCDC sọ pe ipinlẹ Eko nikan ní eeyan 255 lara awọn to ni i bayii.
Awọn to ku ni:
FCT-27
Oyo-10
Kaduna-5
Ondo-2
Kano-1
Lati bi ọsẹ kan ni iye esi ti ajọ naa n gbe sita ti n lọ soke diẹdiẹ, eyi to n kọ awọn alaṣẹ eto ilera lomiinu pe o ṣe e ṣe ki aarun naa tun burẹkẹ si lẹẹkeji.
Wọn ni eyi ko ṣẹyin bi awọn eeyan ko ṣe tẹle ilana eto idaabobo mọ, ti onikaluluku si n ṣe nkan to wu u jakejado orilẹ-ede Naijiria.
Èèyàn 59 míràn ló lùgbàdì coronavirus ní Nàìjíríà lánàá
Fun igba akọkọ lati ọjọ pipẹ, ipinlẹ Eko ko si lori atẹ esi ayẹwo awọn eeyan to ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiriai.
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC. gbe jade ni ọjọ Abamẹta.
Esi lati ipinlẹ mẹjọ pere ni wọn fi sita, ko si si Eko lara wọn. Eeyan mọkandinlọgọta si lo ni i.
Kaduna-28
Rivers-9
Ogun-8
Ondo-8
Kano-2
Niger-2
Kwara-1
Plateau-1
Èèyàn 223 míràn ló lùgbàdì coronavirus ní Nàìjíríà lánàá
Bi ọrọ Covid 19 se ri ni Naijiria lanaa ree:
Ipinlẹ Eko ni 85
FCT-35
Akwa Ibom-24
Enugu-18
Plateau-13
Rivers-10
Abia-7
Ebonyi-6
Anambra-5
Adamawa-4
Bauchi-3
Imo-3
Ogun-3
Oyo-3
Kwara-2
Osun-1
Taraba-1
- 'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n'
- Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé
- Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí
- Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀
- Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé
- Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika
Coronavirus kò pa ẹnìkankan lánàá Ọjọ́bọ̀ ní Nàìjíríà, àmọ́ èèyàn ọgọ́sàn án 180 míì ló ṣẹ̀ṣẹ̀ kóo
Ọgọsan ọmọ Naijiria lo tunko arun coronavirus l'Ọjọbọ gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria loju opo Twitter rẹ.
Niṣe ni arun ọhun n fi ojoojumọ pọ si papaa julọ nipinlẹ Eko, eeyan mẹtadinlaadọrun lo lugbadi covid-19 lati ipinlẹ Eko nikan l'Ọjọbọ.
Ti ipinlẹ Oyo naa gberu sii nibi ti eeyan mọkanlelaadọta to ko arun naa.
Mẹwaa lo larun coronavirus lati Plateau, mẹrin l'Edo, eeyan mẹta lo larun naa nipinlẹ Ekiti ati Ogun.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 14
Meji meji lo ko covid-19 l'Ọjọbọ ni Bauchi, Kaduna ati Niger nigba ti ẹni kọọkan lugbadi arun ọhun lati ipinlẹ Kano, Ondo, Osun ati ipinlẹ Rivers.
Eeyan 59,748 lo ti ri iwosan ninu awọn 63,508 ti ayẹwo fihan pe wọn larun coronavirus ni Naijiria.
Ko si ẹni to ku nipasẹ coronavirus l'Ọjọbọ ni Naijiria, eeyan 1,155 to ti ku naa si ni o wa loju Twitter ajọ NCDC.
Coronavirus gbẹ̀mí èèyàn mẹ́rin lánàá Ọjọ́rú ní Nàìjíríà, èèyàn márùndínlọ́gọ́jọ 155 míì tún kóo
Eeyan mẹrin ni coronavirus ṣekupa ni Naijiria l'Ọjọru nigbaa ti eeyan marunlelaadọjọ(155) mii tun lugbadi aarun ọhun lọjọ kẹrin oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Marunlelọgọrin ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti mẹtalelogun wa lati olu ilu Naijiria, Abuja.
Ẹni mejidinlogun lo ṣe kongẹ arun ọhun nipinlẹ Ondo, eeyan mẹjọ lo ni arun naa lati ipinlẹ Ogun.
- DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́''
- Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná
- Kàyééfì! Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72
- Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
- A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde
Eeyan marun un marun un lo lugbadi covid-19 nipinlẹ Oyo, kaduna, ati Taraba l'Ọjọru ni Naijiria.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 15
Mẹta lo karun coronavirus ni Kano, meji wa lati Rivers, eeyan kan lo larun naa lati Bauchi.
Eeyan 63,328 lo ti lugbadi coronavirus ni Naijiria bayii, ṣugbọn eeyan 59,675 lo ti ri iwosan.
Eeyan 1,155 ni covid-19 ti ṣekupa bayii ni Naijiria.
Èèyàn mẹ́tàdínlógóje 137 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun ọgọ́ta wá láti ìpínlẹ̀ Eko
O dabi ẹni pe coronavirus tun ti n gbilẹ si diẹ diẹ lorilẹede Naijiria. Eeyan eeyan mẹtadinlogoje lo ko aarun naa lọjọ Iṣẹgun.
Ọgọta eeyan lati ipinlẹ Eko lo ni aarun naa eyi to pọju ninugbogbo ipinlẹ lọjọ Iṣẹgun.
Ipinlẹ Abia lo ṣe ipo keji nibi ti eeyan mọkanlelogun ti lugbadi aarun ọhun.
Eeyan mejidinlogun lo laarun naa lati Abuja, mẹtala lati Rivers, marun un lati ipinlẹ Kaduna nigba ti eeyan mẹrin wa lati Oyo.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 16
Eeyan mẹta lo lugbadi aarun naa lati Edo nigba ti eeyan meji meji ni aarun covid-19 lati Delta, Imo, Kano ati ipinlẹ Ogun.
Ẹni kọọkan lo ko aarun coronavirus lọjọ Iṣẹgun lati Bauchi, Gombe, Nasarawa, Niger ati Osun.
O ti di eeyan 63,173 ti ayẹwo ti fihan pe wọn ni coronavirus lapapọ ni Naijiria bayii.
Eeyan 59,634 lo ti jajabọ lọwọ aarun coronavirus bayii.
Èèyàn mọ́kànléláádọta ló wá láti ìpínlẹ̀ Eko nínú èèyàn 72 tó kó ààrùn covid-19 lọ́jọ́ Ajé
Ipinlẹ Eko lawọn to lugbadi aarun coronavirus lọjọ Aje ọjọ kẹta oṣu kọkanla ọdun 2020 ninu awọn mejilelaadọrin ti ajọ NCDC kede.
Eeyan mọkanlelaadọta lawọn to ko aarun naa nipinlẹ Eko nikan.
Olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lo ṣe ipo keji pẹlu eeyan mẹfa, nigba ti ipinlẹ Ogun tẹ le e nibi ti eeyan mẹrin ti fara kaasa aarun naa.
Eeyan mẹta lati Kaduna, meji ni Niger, Ondo ati Plateau lo ni covid-19 lọjọ Aje.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 17
Ẹnikọọkan lo ko aarun ọhun lati ipinlẹ Katsina ati ipinlẹ Oyo.
Lapaapọ eeyan 63,036 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko aarun corinavirus lorilẹede Naijiria.
Eeyan 1,147 si ni aarun coronavirus ti ṣekupa lorilẹede Naijiria bayii.
Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú
Eeyan mọkanlelaadọfa lo ko aarun coronavirus kaakiri orilẹede Naijiria lanaa ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ kinni oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Ipinlẹ Eko ni mọkandinlaadọta ninu awọn eeyan ọhun ti wa.
Olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lo ṣe ipo keji pẹlu ọgbọn eeyan to ṣẹṣẹ fara kaasa aarun naa.
Eni mẹwaa lo ko covid-19 nipinlẹ Plateau lọjọ Aiku nigba ti eeyan mọkanla laarun naa lati ipinlẹ Rivers.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 18
Eeyan merin lo ko aarun naa l'Ogun, mẹta ni Kaduna ati Oyo nigba ti ẹnikan lugbadi aarun naa nipinlẹ Osun.
Lapaapọ eeyan 62,964 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko aarun corinavirus lorilẹede Naijiria.
Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́tà
Ènìyàn 162 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹ́gẹ́ bi àjọ tó n mójú tó ń àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) se sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lọ́ja àbámẹ́tà. Ìpínlẹ̀ mẹ́rìnlá lo ni ààrun náà.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 62,853, eyan 58,675 ti ri iwosan, 1,144 si ti ku.
Gombe-54
FCT-35
Lagos-26
Ogun-12
Plateau-10
Rivers-10
Kaduna-4
Ekiti-3
Edo-2
Osun-2
Bayelsa-1
Imo-1
Ondo-1
Oyo-1
Èèyàn 118 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé
Eniyan 118 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbodun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe sọ ninu ikede to fi sita lalẹ ọjọ Aje, ipinlẹ mẹsan an, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti wa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 61,558, eyan 56,697 ti ri iwosan, 1,125 si ti ku.
Bi apapọ wọn ipinlẹ to ṣẹṣẹ ni arun naa ṣe lọ ree:
Lagos-51
Rivers-26
Imo-12
Osun-8
Plateau-6
FCT-5
Kaduna-4
Ogun-3
Edo-2
Niger-1
Èèyàn 133 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 133 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede yii.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 61,440 eeyan ti arun ọhun ti kọlu ni Naijiria, awọn 1,125 ti dagbere faye, nigba ti awọn 56,611 ti moribọ.
Bi awọn to ṣẹṣẹ ni arun naa ṣe lọ ree:
Eko-90
Rivers-13
FCT-8
Kaduna-8
Oyo-6
Ondo-3
Katsina-2
Nasarawa-2
Plateau-1
Èèyàn 4,161 bọ́ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun aijiria,NCDC ti kede pe eeyan 4,161 t bọ lọwọ arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko, wọn si ti pada sile wọn layọ ati alaafia, ṣugbọn awọn 113 tuntunmiran tun ni arun ọhun.
Ipinlẹ Eko ati Kaduna lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC fi lede nipa awọn to ṣẹṣẹ ni coronavirus.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 37, Abuja ni 16 nigba ti ipinlẹ ogun n sare tete tẹle wọn lẹyin pẹlu eeyan mọkanla.
Awọn ipinlẹ to ku ni:
Plateau-11
Taraba-8
Rivers-7
FCT-6
Enugu-4
Niger-4
Edo-3
Delta-2
Imo-2
Benue-1
Kano-1
Èèyàn méjìlà lé lúgba ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ẹtì
Eayan mejila le lugba lo lugbadi aarun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Ẹti, ọjọ kẹrindinlogunoṣu kẹwaa ọdun 2020 yii.
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo kede rẹ loju opo Twitter rẹ.
Eeyan marundinlaadọrun un ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko nikan, nigba ti mejilelaadọrin wa lati ipinlẹ Oyo.
Ipinlẹ Ogun leeyan mọkanla nibẹ, eeyan kan ṣoṣo lo wa lati ipinlẹ Oṣun.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 19
Eeyan mọkanla lo kaarun naa lati ipinlẹ Plateau, mẹfa lati Katsina, marun un ni Kaduna nigba ti mọkanlelogun wa lati Abuja.
Lapapọ bayii, eeyan 61,194 lo tu laarun naa ni Naijiria, nigba ti 52,304 ti ri iwosan, eeyan 1,119 lo si ti ba aarun naa lọ.
Èèyàn 179 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 179 miran ti darapọ mọ awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Amọ, ko si ẹni ti arun naa pa lọjọru.
Lagos-116
Anambra-20
FCT-9
Oyo-9
Rivers-9
Delta-3
Nasarawa-3
Edo-2
Kaduna-2
Ogun-2
Plateau-2
Ekiti-1
Osun-1
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 60,834 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Apapọ iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 jẹ ẹgbẹerun kan le ni mẹrindinlọgọfa,1,116.
Èèyàn 225 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà l'Ọjọ́rú
Eeyan kan lo padanu ẹmi rẹ lọwọ aarun Covid-19 lorileede Naijira lọjọ Isegun to kọja yi ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun NCDC kede.
Ni bayi awọn eeyan tuntun to lugbadi aarun naa jẹ marundinlọgbọnlenigba,225.
Ipinlẹ Eko lo ṣi le tente pẹlu eeyan marundinlaadọsan,165 ti Abuja si tẹle pẹlu eeyan mẹtadinlogun,17.
Apapọ iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 jẹ ẹgbẹerun kan le ni mẹrindinlọgọfa,1,116.
Awọn eeyan ti aarun Covid-19 ti ran l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun lọna ọgọta ati aarundinlọgtalelgbẹta (60,655) bayii.
Èèyàn 164 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà
Ipinlẹ Eko ati Abuja lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe sita nipa awọn to ni coronavirus.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 64, Abuja si ni 24.
Awọn ipinlẹ yooku ni :
Enugu-20
Kaduna-11
Oyo-11
Plateau-8
Ondo-7
Anambra-4
Nasarawa-3
Osun-3
Ebonyi-2
Imo-2
Benue-1
Katsina-1
Ogun-1
Èèyàn 163 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn coronavirus ní Nàìjíríà
Ipinlẹ Eko ati Kaduna lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe sita nipa awọn to ni coronavirus.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 113, Kaduna si ni 21.
Awọn ipinlẹ yooku ni :
Osun-8
Ondo-5
Oyo-5
Ogun-3
Bayelsa-2
Taraba-2
Edo-1
FCT-1
Katsina-1
Plateau-1
Lọwọlọwọ, o ti pe 60,266 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria. Awọn 51,735 ti ri iwosan, 1,115 si ti ku.
Èèyàn 111 ní àrùn Coronavirus ràn ní Nàìjíríà ní 10/10/2020
Awọn eeyan ti aarun Covid-19 ti ran l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun lọna ọgọta ati mẹtalelọgọrun (60,103) bayii.
Eyi ribẹ ẹ lẹyin ti eyan mọkanlelaadọfa, 111, ni ni ọjọ Satide, gẹgẹ bi esi ayẹwo ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe fi ikede sita.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 20
Eeyan 1,115 ni aarun naa ti sẹkupa ni Naijiria, nigba ti 51,711 ti ri iwosan.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 213 miran tuntun mi ti darapọ mọ awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹsan-an.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 58,062 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Iye awọn to ku lọwọ arun naa si ti di 1,103 ti ara awọn 49,606 si ti ya lẹyin itọju.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 21
Ninu ikede ti wọn fi soju opoo wọn bakan naa Ajọ NCDC sọ pe awọn ṣeṣi kede pe eeyan kan ku ni Bayelsa lọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹsan.
Wọn ni ọrọ yi ko ri bẹ ati pe iye apapọ iye awọn ti ara wọn ya jẹ 364 ti wọn ba fi iye awn to gba itọju nile ni Katsina kun un.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 22
Èèyàn 125 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́bọ̀
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 125 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 849 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Èèyàn 111 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 111 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 724 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 23
Èèyàn 176 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 176 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 613 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 24
Èèyàn 195 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ajé
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 195 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 437 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 25
Èèyàn 97 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Àìkú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 97 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57,242 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 26
Èèyàn 189 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 189 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57,145 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 27
Èèyàn 221 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 221 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 56,,956 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 28
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC kede esi aadọrun eeyan to tun ṣẹṣẹ ni
Ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita lori Twitter, ipinlẹ mẹtadinlogun, ati ilu Abuja ni esi ayẹwo naa ti wa.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 29
Eeyan 126 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́rú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 126 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 56,604 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 30
Eeyan 90 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Iṣẹ́gun
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC kede esi aadọrun eeyan to tun ṣẹṣẹ ni, lọjọ Iṣẹgun.
Ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita lori Twitter, ipinlẹ Eko ni eeyan mẹtalelọgbọn.
Plateau-27
Kaduna-17
Ogun-6
FCT-4
Anambra-1
Ekiti-1
Nasarawa-1
Apapọ awọn to ti ni aarun naa jẹ 56,478
44,430 ti gba iwosan
Awọn to ti ku si jẹ 1,088
Àjọ NCDC tún kéde èèyàn 132 tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ní coronavirus lọjọ Aje ní Nàìjíríà
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede esi eeyan mejilelaadoje to tun ṣẹṣẹ ni, lọjọ Aje.
Ipinlẹ Eko, Gombe ati Plateau, lo wa ni ipo kinni si ipo kẹta ninu esi tuntun naa.
Ko ti i ju ọjọ kan lọ ti ajọ naa kede eeyan mọkandinlọgọrin pere to ṣẹṣẹ ni aarun naa, eyi to ti i kere julọ lẹyin ọpọlọpọ oṣu.
Esi ayẹwo tuntun naa niyi:
Lagos-52
Gombe-27
Plateau-17
Kwara-10
Enugu-9
Ogun-9
Katsina-3
Ekiti-2
Bauchi-1
Osun-1
Rivers-1
Lọ́jọ́ Ajé, agbára coronavirus já wálẹ̀, èèyàn 79 péré ni NCDC kéde pé ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ní i
O dabi ẹni pe itankalẹ aarun coronavirus ti n dinku lorilẹ-ede Naijiria bayii.
Eyi ko sẹyin esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, fi sita lọjọ Aiku, to safihan pe eeyan mọkandinlọgọrin pere lo ṣẹṣẹ ni.
Numba yii jina pupọ si iye ti wọn ti ma n kede tẹlẹ lati bi oṣu melo kan.
Esi ayẹwo tuntun naa lọ bayii:
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 31
Ni bayii, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria ti pe 56,256. Lara wọn ni eeyan 44,152 ti gba iwosan, ti awọn 1,082 si ti ku.
- Ọsán jáá! òṣèré àti ọ̀jọ̀gbọ́n Tiatia Unilorin, Ayo Akinwale jáde láyé
- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń fi "shisha" ṣagbeji ara
- Wo nǹkan tí ìjọba àpapọ̀ yóò ṣe fáwọn tó ń ta 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' àti 'fònàgáú'
- Daddy Freeze túbá! Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo
Lọjọ Aiku
Eniyan 160 lo tun ṣẹṣẹ ni aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbodun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe sọ ninu ikede to fi sita lalẹ ọjọ Satide, ipinlẹ mejila, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti wa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 56,177. Eeyan 44,088 ti ri iwosan, 1078 si ti ku.
Eyi ni ibi ti nkan de duro ni ipinlẹ kọọkan fun:
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 32
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 197 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ́bọ̀.
Amọ, awọn eniyan 200 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ́bọ̀ ohun.
Nibayii, eeyan 1,075 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,829 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 610 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọbọ ṣe lọ ree:
Plateau-83
Eko-48
Kaduna-17
FCT-16
Ogun-11
Katsina-7
Imo-4
Edo-3
Nasarawa-3
Rivers-2
Bayelsa-1
Oyo-1
Osun-1
Ènìyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 176 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ́ọ̀rú.
Amọ, awọn eniyan 276 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ́ọ̀rú ohun.
Nibayii, eeyan 1,070 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,632 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 610 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Iṣẹgun ṣe lọ ree:
FCT-40
Eko-34
Plateau-26
Enugu-14
Delta-12
Ogun-12
Ondo-9
Oyo-8
Ekiti-6
Ebonyi-4
Adamawa-2
Nasarawa-2
Kwara-2
Rivers-2
Edo-1
Osun-1
Bauchi-1
Ènìyàn 296 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 296 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Ìṣẹ́gun.
Amọ, awọn eniyan 103 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ Iṣẹgun ohun.
Nibayii, eeyan 1,067 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,456 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 334 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Iṣẹgun ṣe lọ ree:
Plateau-183
Eko-33
FCT-25
Ogun-16
Oyo-7
Ekiti-6
Kwara-5
Ondo-5
Anambra-3
Imo-3
Nasarawa-3
Rivers-2
Gombe-2
Edo-2
Akwa Ibom-1
Ènìyàn 309 ló rí ìwòsàn gbà lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ajé
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 155 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Aje.
Amọ, awọn eniyan 309 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ Aje ohun.
Nibayii, eeyan 1,061 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,160 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43,231 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree:
Ondo-42
Plateau-25
Rivers-16
Ebonyi-10
Abia-9
Ogun-9
FCT-9
Osun-7
Katsina-6
Kaduna-6
Ekiti-4
Taraba-4
Edo-3
Anambra-2
Akwa Ibom-2
Kano-1
Ènìyàn 100 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Aiku
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 100 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Aiku.
Ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Nibayii, eeyan 1,057 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,005 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 42,922 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree:
Eko-39
FCT-22
Kaduna-19
Oyo-7
Ebonyi-6
Edo-3
Katsina-1
Ekiti-1
Bauchi-1
Nasarawa-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 162 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Abameta, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Nibayii, eeyan 1,054 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 54,905 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 42,922 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree:
Eko-53
Gombe-21
Oyo-19
Delta-12
Ondo-11
Plateau-10
Ebonyi-9
FCT-6
Kwara-6
Kaduna-5
Rivers-3
Ogun-2
Anambra-2
Imo-2
Ekiti-1
Ènìyàn 156 míràn ló tún kó Coronavirus ní Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 156 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Ẹti, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Nibayii, eeyan 1,051 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 54,743 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 42,816 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Eko-36
FCT-35
Oyo-29
Kaduna-10
Abia-9
Osun-5
Ogun-5
Enugu-5
Rivers-4
Nasarawa-3
Ekiti-3
Imo-3
Edo-2
Kwara-2
Katsina-2
Plateau-2
Niger-1
Èèyàn 125 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede afikun eeyan marundinlaadoje 125 pẹlu arun COVID-19 lorilẹede Naijiria.
Lalẹ Ọjọbọ ni ajọ NCDC kede rẹ loju opo ayelujara Twitter rẹ @NCDCgov.
Ipinlẹ Eko pada sori oke tente tabili ojoojumọ awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti ni coronavirus lorilẹede Naijiria lẹyin ti ipinlẹ Plateau ti n ṣiwaju awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti n ko arun naa.
Pẹlu afikun tuntun yii, o jasi pe iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni aarun yii lorilẹede Naijiria ti di ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ẹgbẹta o din mejila, 54, 588.
Eko eeyan mejilelogoji (42), Ilu Abuja eeyan marundinlọgbọn (25), ipinlẹ Katsina eeyan mẹrinla (14), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Kwara eeyan mẹjọ (8), ipinlẹ Ondo eeyan meje (7), ipinlẹ Delta eeyan mẹrin (4), ipinlẹ Anambra eeyan mẹta (3), ipinlẹ Oyo eeyan mẹta (3) ti ipinlẹ Edo, Ogun ati ṣun si ni meji meji. Ipinlẹ Cross river lo kere ju pẹlu eeyan kan ni Ọjọbọ.
Èèyàn 216 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan okoolelugba o din mẹrin miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ojilelugba ati meje, 54,463 eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lọjọru pẹlu eeyan mọkandinlọgọta (59), ipinlẹ Rivers eeyan mẹtadinlọgbọn (27), ipinlẹ Abia eeyan mejilelogun (22), ipinlẹ Eko eeyan ogun (20), ipinlẹ Ọyọ, (18), ipinlẹ Enugu eeyan mẹtadinlogun (17), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ogun eeyan mẹwaa (10), ipinlẹ Ebonyi eeyan mẹrin (4) Ipinlẹ Ekiti mẹrin (4), ipinlẹ Ọṣun eeyan mẹrin (4), Delta eeyan mẹta (3), ipinlẹ Edo eeyan mẹta (3), ipinlẹ Akwa Ibom eeyan meji (2), ipinlẹ Bauchi eeyan kan ṣoṣo (1).
Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan ojilelugba o din ẹyọ kan miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ojilelugba ati meje, 54,247 eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Iṣẹgun pe "Ni ọjọ kinni. oṣu kẹsan an, ọdun 2020, eeyan eeyan ojilelugba o din ẹyọ kan lo tun ṣẹṣẹ ko aarun naa ti eeyan mẹwaa si jade laye lorilẹede Naijiria."
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lọjọ Iṣẹgun pẹlu eeyan mẹrindinlọgọfa (116), olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mẹtalelọgbọn (33), ipinlẹ Eko eeyan mọkandinlogun (19), Ipinlẹ Ekiti mejila (12), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ogun eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ebonyi eeyan mẹjọ (8) ipinlẹ Benue eeyan meje (7), ọkọọkan ipinlẹ Abia, ati Delta ni marun un (5), ipinlẹ Ondo mẹrin (4), ipinlẹ Edo eeyan mẹta (3), ipinlẹ Imo eeyan meji (2), ipinlẹ Ọṣun eeyan meji (2) Bauchi eeyan kan ṣoṣo (1).
- Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run
- Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ "Secondary" tí yóò wọlé ní October yìí?
- Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi
- Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀
Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyan mẹtalelogoje miran to kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Aje pe "Ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020, eeyan mẹtalelogoje lo tun ṣẹṣẹ ko aarun naa ṣugbọn ko si akọsilẹ iku kankan lorilẹede Naijiria."
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lojumọ lọjọ Aje pẹlu eeyan marundinlogoji (35), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanlelogun (21), ipinlẹ Eko eeyan mọkandinlogun (19) olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mẹtala (13), Ebonyi eeyan mẹsan (9), ọkọọkan ipinlẹ Adamawa, Enugu ati Katsina ni meje (7), ipinlẹ Edo mẹfa (6), ipinlẹ Kwara marun un (5), ipinlẹ Osun mẹta (3), ọkọọkan ipinlẹ Anambra, Kano, Benue ni eeyan neji, ipinlẹ Benue, Borno ati Sokoto ni eeyan kọọkan (1).
Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyam mejidinlogoje miran to kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹtalelaadọta eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Aiku.
Bakan naa lo fi idi rẹ mulẹ pe eeyan meji miran tun ti jade laye nipasẹ aarun naa.
Pẹlu eyi iye awọn eeyan ti ajakalẹ aarun coronavirus ti ran jade laye ti di ẹgbẹrun kan o le mẹtala.
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lojumọ lọjọ Aiku.
Fún ọjọ́ kẹ́ta, ìpínlẹ̀ Plateau gbé ipò kínní lórí àtẹ COVID-19! Èèyàn 250 míràn lárùn náà
Igba o le aadọta eeyan ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC tun ti kede pe o ko aarun COVID-19 lọjọ Abamẹta.
Eleyi ti mu ki apapọ iye awọn to ti laarun naa lorilẹede Naijiria o di ẹgbẹrun mẹtalelaadọta ati okoolelẹẹdẹgbẹrin ati meje (53,727)
Ajọ NCDC ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe " ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020, Igba o le aadọta eeyan lo tun kun iye awọn to ni aarun naa bẹẹni ko si ẹni to ku nipasẹ ajakalẹ aarun ọhun."
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ẹgbẹrun mọkanlelogoji eeyan o le ọọdunrun ati mẹrinla (41314) ni iye awọn to ti gba iwosan lọwọ aarun naa ti ẹgbẹrun kan o le mọkanla si ti jade laye.
Fun ọjọ kẹta ni ṣisẹ n tẹle, ipinlẹ Plateau lo tun gbegba oroke bayii laarin awọn ipinlẹ ti ọwọja aarun naa n pọ si lọwọlọwọ lorilẹede Naijiria.
Eeyan mọkandinlaadọrin ni wọn tun kede pẹlu aarun naa lọjọ Abamẹta.

Fún ọjọ́ kéjì léra, ìpínlẹ̀ Plateau gbé ipò kíní lórí àtẹ COVID-19! Èèyàn 160 ló tún forí kó o
Fun ọjọ keji lera bayii, ipinlẹ Plateau ni o n lewaju laarin awọn ipinlẹ ti COVID-19 ti n ṣọṣẹ julọ lorilẹede Naijiria lori onka olojoojumọ awọn to n ni aarun naa eleyii ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita.
Ninu atẹjade iye awọn to laarun naa, eyi ti ajọ NCDC fi sita lalẹ ọjọ Ẹti, ninu ọgọjọ eeyan to kun iye awọn to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Ẹti, mẹrinlelogoji ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Plateau.
Gẹgẹ bi atẹjade ọhun ṣe sọ, ipinlẹ Eko lo tẹle e pẹlu eeyan mẹtadinlọgbọn.
Bi atupalẹ awọn ipinlẹ yooku ti awọn eeyan to kun iye awọn to laarun COVID-19 ṣe lọ niyi:
Bi ẹ ko ba gbagbe, ni Ọjọbọ, marundinlaadọrun lawọn to ni aarun naa lati ipinlẹ Plateau.
Eyi to fihan pe l'Ọjọbọ ati Ẹti, ipinlẹ Plateau lo moke pẹlu iye awọn to laarun naa lorilẹede Naijiria.
Ipò kíní ré sórí ìpínlẹ̀ Plateau! Èèyàn 296 ló forí kó Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́bọ
Ènìyàn mẹ́rìndínlọ́ọ̀dúnrún ló tún lùgbàdì ààrùn Covid-19 lọ́jọ́bọ gẹ́gẹ́ bi atẹjade àjọ tó n gbogun ti ajakalẹ ààrun lórílẹ̀-èdè Naijiria ṣe sọ.
Iye ènìyàn to lùgbàdì ààrùn náà ni ọjọ́bọ yìí tún pọwọ́ lọ sókè díẹ̀ si ju ti ọjọ́rú àti ọjọ́iṣẹgun lọ.
Ẹ̀wẹ̀, o jọ bi ẹni pé ipińlẹ̀ Plateau ń burẹkẹ si ni nítori ojojúmọ́ ni àwọn ènìyàn to n lùgbàdì ààrùn náà ń pọ̀ si níbẹ̀ bi wọ́n ṣe ti ni ènìyàn marun lélọ́gọ́rín lọ́jọ́bọ.
Ní báyìí ẹgbẹ̀rún mẹ́tàléláàdọ́ta àtí ọọdúnrún le díẹ̀ lo ti lugbadi ààrùn náà.
Ìpínlẹ̀ mẹ́tàdílógún ni àwọn ènìyàn to ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ti jẹyọ ni àná
Plateau-85
Enugu-46
Oyo-31
Lagos-21
Rivers-20
FCT-15
Kaduna-13
Bauchi-12
Delta-11
Ekiti-11
Akwa Ibom-7
Ebonyi-6
Kwara-5
Ogun-4
Osun-4
Gombe-3
Niger-2
Ibi ti ìpińlẹ̀ kọ̀ọ̀kan de dúró ni Naijiria rèé
NCDC ní ènìyàn 296 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà
Ikéde àbájáde àyẹ̀wò àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ni Nìàjíríà kò ju igba àti mọ́kànlélógún lọ lọ́jọ́rú.
Ó ti di ọjọ́ mẹ́rin lérawọ́n báyìí ti àbájade ìye ènìyàn to ni ààrùn Covid-19 ti ń já wálẹ̀ lójoojúmọ.
Ibèérè ti ọ̀pọ̀ ń bèèrè ni pé, ṣe à ti bori ààrùn náà ni tàbi kò sí àyẹwò bó ti tọ́ àti bóti yẹ mọ́?
Nínú àbájáde àyẹ̀wò tí ọjọ́rú, ìpínlẹ̀ Plateau náà lo tú wà lókè ténté pẹ̀lú ènìyàn ọgọ́ta, o fi mẹ́wàá pọ̀ ju ti àná lọ.
FCT lo tẹ̀lé pẹ̀lú mẹ́tàlélagbọ̀n, Kaduna náà pọ́wọ́ lèé pẹ̀lú mẹ́rìndinlógu, Rivers ní ènìyàn méjìdínlógún ti Ipinlẹ Eko sì wà ni ipò kaarún pẹ̀lú mẹ́tàdílógún.
Ó ti dí ènìyàn ẹgbẹ̀rúnlọ́nà mẹ́tàléláàdọ́ta àtí makàlelógún to ti lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà
Ènìyàn mẹ́ta tún ti jẹ́ Ọlọ́run nípè, ó sì ti dí ẹgbẹ̀rún kan àti ènìyàn mẹ́wàá to ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn báyìí.
Plateau-60
FCT-33
Kaduna-26
Rivers-18
Lagos-17
Enugu-9
Kwara-9
Ondo-9
Nasarawa-6
Gombe-5
Anambra-5
Delta-4
Abia-4
Imo-3
Edo-2
Ogun-2
Oyo-2
Osun-2
Bauchi-1
Kano-1
NCDC ní ènìyàn 252 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà
Bí ọjọ́ ṣe n gorí ọjọ́ ló dàbí pe ọwọ́jà àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus ń rọ́lẹ̀ síi ni orílẹ̀-èdè Náìjíríà.
Ènìyàn òjìlélúgbà àti méjìlá ni àwọn to tun ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn náà báyìí.
Ṣùgbọ́n lọ́tẹ̀ yìí ìpò kẹrin ni ìpińlẹ̀ Eko to jẹ́ orírun ààrùn náà ni Nàìjíríà wà ní ipò kẹrin lonìí, nígbà ti Ipinlẹ Plateau wà lókè ténté pẹ̀lú ààdọ́ta ènìyàn.
Àbájáde èsì ayẹwò to jáde lánáà kan ìpińlẹ̀ méjìdin lógun
Ènìyàn mẹ́ta lo tun bá ààrùn náà rin láná, eyí si ti mú iye ènìyàn tó ti kú wá si ẹgbẹ̀run kan àti méje.
Ní báyìí ẹgbẹ̀rún méjìléláàdọ́ta ó lé ẹgbẹ̀rin ló ti lùgbàdi ààrùn náà ni Naijiria, sùgbọ́n ènìyàn ẹgbẹ̀rún ọgọ́jì dín díẹ̀ ló ti ri ìwòsàn.
Plateau-50
Enugu-35
Rivers-27
Lagos-26
FCT-18
Kaduna-18
Ekiti-10
Kano-10
Taraba-9
Anambra-8
Edo-8
Oyo-8
Delta-7
Ogun-6
Abia-5
Bayelsa-5
Ebonyi-1
Osun-1
NCDC ní ènìyàn 321 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà
Iye ènìyàn to tún lùgbàdì ààrùn Coronavirus tun dín ẹyọkan si ti àná.
Nínú ìkéde ti àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) fi síta lónìí, lójú òpó twitter rẹ̀ lo ti ṣe àtúpalẹ̀ àbájade àyèwò àwọn ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan ní Naijiria.
Ní ojú tó mọ́ lónìí ènìyàn ojìlélọ́ọ̀dúnrún àti ẹyọkan ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdi ààrùn Corornavirus ni Naijiria
Àpapọ̀ iye ènìyàn to ti ni ààrùn Covid-19 ni Nàìjíríà ti dí ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà lààdọ́ta le méjì àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀tààbọ̀ dín méjì.
Ènìyàn méjì tún d'olóògbé lánàá, èyí si ti mú iye ènìyàn ti ààrùn Covid-19 ti ré sí òrun alákeji di ẹgbẹ̀run kan àti mẹ́rin.
Àtúpalẹ̀ ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan rèé gẹ́gẹ́ bi o ṣe lọ lánàá
Lagos-98
FCT-34

Kaduna-30
Nasarawa-25
Benue-21
Plateau-17
Rivers-15
Adamawa-11
Ogun-11
Enugu-9
Edo-8
Delta-7
Ekiti-7
Gombe-5
Ebonyi-4
Bayelsa-3
Kano-3
Ondo-3
Cross River-2
Imo-2
Kebbi-2
Niger-2
Abia-1
Bauchi-1
Ìpínlẹ̀ Eko náà ló si ń léwájú nínú awọn ìpínlẹ̀ to ni ààrùn Coronavirus
NCDC ní ènìyàn 322 míràn ló tún fara kásá ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà
Yàtọ̀ sí ìròyìn tó gbòde ni àná ọjọ́ Àìkú lójú òpó Twitter àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjírà NCDC nípa bi iye ènìyàn to ni ààrun Covid-19 ṣe gbẹ́nu sókè, ọ̀tọ̀ ló rin nígbà ti iye ènìyàn ti ọjọ́ Àìkú jáde.
Àjọ NCDC kéde pé ènìyàn ojìlélọ́ọ̀dúnrún àti méjì ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdi ààrùn Corornavirus, èyí jẹ́ ìdajì iye ènìyàn ti wọ́n kédé lọ́jọ́ Satide.
Ní bayìí ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà méjì lé lààdọ́ta àti ọ̀tàlénígba ó din mẹ́ta ló ti ni ààrùn náà lápapọ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, sùgbọ́n ènìyàn tó dín díẹ̀ lẹ́gbẹ̀rún mọ́kàndílógójì ló ti gba ìwòsàn ti wọ́n sì ti wà ni ilé wọ́n.
Ènìyàn méjìlélẹ́gbẹ̀rún ni ọwajà ààrùn náà ti le lọ sí ọ̀rún alákeji.
Báyìí ni àtúpalẹ̀ àwọn to ni ààrùn náà nípìnlẹ̀ kọ̀ọ̀kan ṣe lọ
Lagos-130
Bauchi-36
FCT-25
Edo-17
Bayelsa-14
Ogun-14
Oyo-14
Anambra-13
Kaduna-12
Ondo-11
Abia-10
Osun-6
Plateau-5
Kwara-5
Kano-4
Ebonyi-3
Sokoto-2
Borno-1
Ipò ti ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan wà rèé lọ́wọ́lọ́wọ́
Definition of Coronavirus: NCDC kéde èèyàn 601míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
Àjọ tó ń gbogun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kéde pé ènìyàn mọ́kànlélẹ́gbẹ̀ta ènìyàn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid -19 ni Nàìjíríà, bí ènìyàn to tó lé ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rin ṣe ti kú lágbàyé báyìí.
NCDC kéde èyí lọ́jọ́ sátidé pé ìpínlẹ̀ Eko to jẹ́ orísun ààrun náà lo gbégba orókè jùlọ pẹ́lù irínwo ènìyàn, nígbà ti Abuja ṣe ipò keji pẹlú ènìyàn mẹ́tàdinlógójì.
Àwọn ìpińlẹ̀ to kù ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ Oyo to ni ènìyàn mọ́kandinlógún, Ondo ènìyàn mẹ́rìnlá, Abia, Enugu àti Kaduna ni ènìyàn mẹ́tàlá.
Edo àti Kano ni méjìlá, Kwara ni mọ́kànlá, Ebonyi ní ènìyàn tuntun mẹ́wàá, Nasarawa, ni méje, Ogun ènìyàn mẹ́fà, Osun, Delta àti Niger ni èǹìyàn márùn.
Ìpínlẹ̀ to kù ni Pleatue àti Bayelsa pẹ̀lú ènìyàn mẹ́rin Kastina mẹ́ta, Ekiti àti Imo ni ènìyàn meji.
Ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, NCDC fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ènìyàn kan kú ni ọjọ́ sátide èyí sì ló jẹ́ kí o pé ènìyàn mẹ́tàdínlẹ́gbẹ̀run kan tó ti bá ààrùn Covid -19 rin ni Nàìjíríà.
Sùgbọ́n ní báyìí ènìyàn tó díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rún mẹ́jiléláàdọ́ta ènìyàn lo ti ni ààrùn náà ní Nàìjíríà tí ènìyàn to dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógójì ló ti gbádun ti wọ́n sì ti pada si ilé wọ́n.
Lagos-404
FCT-37
Oyo-19
Ondo-14
Abia-13
Enugu-13
Kaduna-13
Edo-12
Kano-12
Kwara-11
Ebonyi-10
Nasarawa-7
Ogun-6
Osun-5
Delta-5
Niger-5
Plateau-4
Bayelsa-4
Katsina-3
Ekiti-2
Imo-2
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan ọọdunrun le ni ogoji miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Ẹti, ipinlẹ Kaduna si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ẹwẹ, awọn eeyan ọọdunrun le ni mẹrindinlogun miran lo ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn layọ ati alaafia.
Nibayii, eeyan 996 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 51,304 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 37,885 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Kaduna-63
FCT-51
Plateau-38
Eko -33
Delta-25
Gombe-21
Adamawa-21
Edo-20
Katsina-17
Akwa Ibom-11
Ekiti-10
Rivers-9
Ondo-5
Ebonyi-4
Cross River-3
Ogun-3
Sokoto-2
Imo-2
Nasarawa-2
Èèyàn 329 ni ààrùn coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà - NCDC
Ọọdunrun ati mọkandinlọgbọn eeyan ni ajọ NCDC tun kede pe o ti ni Covid-19 ni Naijiria.
Esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita ni Ọjọbọ lati awọn ipinlẹ mọkanlelogun fihan pe:
Lagos-113
Kaduna-49
FCT-33
Plateau-24
Kano-16
Edo-15
Ogun-14
Delta-13
Osun-10
Oyo-8
Ekiti-6
Bayelsa-6
Akwa Ibom-5
Borno-4
Enugu-4
Ebonyi-3
Rivers-2
Bauchi-1
Nasarawa-1
Gombe-1
Niger-1
Ẹ wo apapọ iye ti ipinlẹ kọọkan ni:
Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria pe ẹgbẹrun mejidinlaadọta ati mẹrindinlọgọfa lọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ.
Eyi ri bẹ ẹ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, tun kede ọọdunrun ati mẹtalelaadọrin to tun ṣẹṣẹ ni i.
Ṣugbọn o, ajọ naa ti sọ pe ibudo ayẹwo aarun naa ti pe mẹtalelọgọta jakejado Naijiria, ṣugbọn iṣoro kan to wa nibẹ ni pe awọn to n wa fun ayẹwo ko pọ to o.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 33
Eeyan ọọdunrun le mẹrinlelọgbọn lo gba iwosan lọwọ arun Covid-19 l'Ọjọru, ọjọ kejila, oṣu Kẹjọ, nigba ti awọn irinwo le mẹtalelaadọta miran tun lugbadi rẹ ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 956 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 47,743 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,943 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Lagos-113
FCT-72
Plateau-59
Enugu-55
Kaduna-38
Ondo-32
Osun-26
Ebonyi-20
Ogun-9
Delta-8
Borno-7
Akwa Ibom-6
Oyo-5
Bauchi-1
Kano-1
Ekiti-1
NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede irinwo le mẹtalelogun eeyan to ṣẹṣẹ fara kaasa arun Covid-19 ni Naijiria.
Oru ọjọ Iṣẹgun ni ajọ naa kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ.
Ajọ ọhun tun kede ọtalenigba le mẹta (263) eeyan to gbawosan, ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ sile wọn layọ ati alaafia.
Awọn to ti dero ọrun nipasẹ ajakalẹ arun naa Naijiria ti di 956.
Eeyan 47,290 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, nigba ti eeyan 33,609 lapapọ ti ri iwosan gba.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Lagos-117
FCT-40
Ondo-35
Rivers-28
Osun-24
Benue-21
Abia-19
Ogun-19
Ebonyi-18
Delta-17
Kwara-17
Kaduna-15
Anambra-14
Ekiti-11
Kano-9
Imo-6
Gombe-4
Oyo-3
Taraba-3
Bauchi-1
Edo-1
Nasarawa-1

Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyan mẹwaa din ni ọọdunrun lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Aje, ipinlẹ Eko lo si wa loke tente awọn ipinlẹ ti arun naa tun kọlu lọtun, nigba ti Plateau n tẹle e lẹyin.
Ẹwẹ, ọgọjọ eeyan tuntun miran lo ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn.
Nibayii, eeyan 950 lo ti dero ọrun nitori ajakalẹ arun ọhun ni Naijiria.
Awọn 46,867 lo to ti fara kasa arun naa, ti awọn 33,346 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Eko-82
Plateau-82
Oyo-19
FCT-18
Edo-16
Kaduna-15
Enugu-9
Ogun-9
Kano-8
Kwara-8
Cross River-5
Ondo-5
Rivers-5
Ekiti-4
Imo-3
Borno-2
NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan irinwo le ni mẹtadinlogoji miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ẹwẹ, awọn eeyan mejilelogoje miran lo ti ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn layọ ati alaafia.
Nibayii, eeyan 945 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 46,577 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,186 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Eko-107
FCT-91
Plateau-81
Kaduna-32
Ogun-30
Kwara-24
Ebonyi-19
Ekiti-17
Oyo-8
Borno-6
Edo-6
Kano-4
Nasarawa-3
Osun-3
Taraba-3
Gombe-2
Bauchi-1
Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Àbámẹ́ta
Irinwo le meje eeyan lo gbowosan lọwọ arun Covid-19 lọjọ Abamẹta, nigba ti awọn irinwolelaadọta le mẹta miran tun lugbadi rẹ ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 942 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 46,140 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,044 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
FCT-75
Eko-71
Benue-53
Delta-39
Borno-30
Enugu-25
Plateau-24
Osun-20
Abia-19
Oyo-17
Kaduna-16
Kano-13
Ebonyi-13
Ogun-9
Kwara-7
Ondo-6
Gombe-3
Ekiti-2
Akwa Ibom-1
Rivers-1
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà jàjàbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì
Wọn ti kede eeyan mẹtadinlaadọfa to ṣẹṣẹ jajabọ lọwọ arun Covid-19, bẹẹ naa ni wọn tun kede eeyan 443 miran to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ni Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 936 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa ni Naijiria.
Eeyan 45,687 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo ti awọn 32,637 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Plateau-103
Eko-70
FCT-60
Ondo-35
Edo-27
Rivers-27
Kaduna-20
Osun-19
Borno-18
Oyo-18
Kwara-11
Adamawa-9
Nasarawa-7
Gombe-6
Bayelsa-4
Imo-4
Bauchi-2
Ogun-2
Kano-1
Coronavirus kò rẹ́rìín sí ilẹ̀ Afíríkà mọ́ o
Aarun naa ti tan kalẹ kọja gbogbo awọn ilu nla nla nilẹ Afirika to fi mọ awọn igberiko mii nibi to jẹ wipe awọn irinṣẹ eto ilera perete lo wa nibẹ ti itju alaisan si lee to jọ pupọ.
Ni ọjọbọ ọsẹ, iye awn to lugbadi arun Coronavirus ti rekoja Miliọnu kan ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ eleto ilera lagbaye tilẹ ni ootọ awọn to ko arun naa ju iye ti wọn n sọọ yii lọ fiifii tori aisi ọna ati ṣe ayẹwo eyi to wọpọ lawọn orilẹede.
Idaji awọn to lugbadi arun wọn yi wa lati ilẹ South Afrika. O fẹrẹẹ to eeyan ẹgbẹrun mọkanlelogun to ti ku bayii ti awọn aadọrinlelẹgbẹta si ti ti ri iwosan gba.
Ẹwẹ, ni Naijiria ajọ NCDC kede eeyan ọọdurun le mẹrinlelaadọta to ti fori ko ajakalẹ arun naa lọjọbọ.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 34
Lọjọru ọsẹ, gẹgẹ bi ijade nile ati ipejọpọ ṣe ti n bẹrẹ pada lorilede Naijiria, bẹẹ naa ni itankalẹ arun Coronavirus bẹrẹ si ni fi sihin sọhun.
Ikede ajọ NCDC ni nkan bii aago mọkanla kọja lalẹ ọjọru fi han pe ilu ipinlẹ Eko ti gba ipo iwaju pada ti Abuja si to tẹle e lẹyin. Nibayii, ipinlẹ Jos, Plateau naa ti darapọ mọ awọn aṣaaju ninu lilugbadi Covid-19 pẹlu bo ṣe bọ si ipo kẹta lọjọru.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 35
Ẹwẹ̀ lọjọ Iṣegun to jẹ pe lẹyin ọjọ mẹta lera ti iye awọn to ko Covid-19 ni Naijiria ṣẹṣẹ ja wa silẹ, o tun ti gbera sọ pada lọjọ Iṣẹgun.
Ajọ NCDC kede pe awọn to tọwọ arun naa dero ọrun lapapọ ni Naijiria lọjọ Aje ti di ẹẹwalelẹẹdẹgbẹrun.
Olu ilu Naijiria Abuja lo leke pẹlu iye awọn to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa pẹlu eeyan 90.
Awọn Iroyin tẹẹ le nifẹ si
Apapọ awọn to ko Covid-19 tuntun ni Naijiria si jẹ 304
Lapapọ awọn to ti ni Naijiria bayi jẹ 44,433
Awọn tara wọn ti ya lẹyin itọju si jẹ 31,851.
Lórí Covid-19, àdínkù iye àwọn tó lùgbàdì àrùn náà wáyé lọ́jọ́ mẹ́ta léra
O ma tun ja wa silẹ ju ti tẹlẹ lọọ!
Bẹẹ ni. Iye awọn ti o ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus lorileede Naijiria ti dikun sii pẹlu bi ajọ to n mojuto ajakalẹ arun NCDC ṣe kede pe eeyan 288 pere lo ko arun naa lọjọ Aje.
Ikede yi jẹ igba ẹlẹkẹẹta laarin ọsẹ yii ti awọn to ko Coronavirus yoo dinku si tatẹyinwa.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 36
Ni bayi, apapọ awọn to lugbadi arun naa lati igba to ti bẹrẹ ni Naijiria ti di 44,129.
Ni onka awọn to ti gba itọju tara wọn si ti ya, iye wọn ni Naijiria jẹ 20,663 bayi.
NCDC loju opo wọn sọ pe eeyan 896 lo ti baarun naa lọ.
Ikede adinku yi n waye lasiko igba ti ijọba ipinlẹ Eko naa n sọ pe iye awọn to gba itọju nile t'ara wọn si ti ya ti di 10,946 bayi.
Loju opo NCDC ni wọn ti ṣe alabapin iroyin yi eleyi ti wọn ni o wa lati ọwọ ijọba ipinlẹ Eko
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 37
Coronavirus kò rí ju èèyàn 304 tó forí kó o lọ lọ́jọ́ àìkú
O fẹ dabii pe iroyin ayọ ti n ṣẹlẹ lorilede Naijiria lẹnu ọjọ perete yii leyii ti iye awọn to n ko arun Coronavirus dinku si tatẹyinwa.
Koda awọn eekan to ti lugbadi arun naa ti boode lati sọ pe awọn ti bọ.
Lọjọ aiku, ọjọ keji oṣu kẹjọ dun 2020 gẹgẹ bi ajọ NDDC ṣe fi sita, eeyan mẹrinlelọọdunrun pere ni arun naa kora rẹ ran mọ leyi to ṣi kere si iye ti wọn ti n fi sita fun igba pipẹ.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 38
Ọjọ aiku ni igba akọkọ lẹyin oṣu pupọ ti arun Covid-19 ti bẹrẹ si ni ja rain ni Naijiria ti adinku ba iye awọn eeyan tuntun to ṣẹṣẹ ko arun naa.
Lọjọ Ẹti si Abamẹta iye awọn tuntun to ni Covid-19 ja wa silẹ lati 462 si 386.
Yatọ si ilu Abuja to ni eeyan 130 tuntun awọn ipinlẹ bi Imo ati Adamawa ko ni ju eeyan kọọkan lọ.
Iroyin yi jẹ eleyi to dun mọ ọpọ ọmọ Naijiria ninu ti awọn miran si ti bẹrẹ si ni beere pe ṣe Naijiria ti re kọja ewu arun yi ni.
Loju opo ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC, ikede yi han lori Twitter
Ni bayi awọn eeyan 43,537 ni arun naa ti fara kan lapapọ ni Naijiria
Awọn to ti ri iwosan gba ti ara wọn si ti ya ti to 20,087 ti awọn to ti ba arun naa lọ si jẹ 883.
Ikede ayipada ninu iye awọn to n ko arun yi ni Naijiria n waye lasiko ti awọn orileede mii ni Afirika bi South Afrika n ga si.
Nilẹ toni to mọ, awọn to ti ko arun naa ni South Afirika ti kọja ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta.
Lọjọ Abamẹta Minisita feto ilera wọn kede pe eeyan 10,107 tuntun lo ko arun naa ti awọn to si ti gba tọwọ Covid-19 ku jẹ 8,153
Èèyàn 462 míràn tún lùgbàdì àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà l'ọjọ́ Ẹtì
Lọjọ ọdun Ileya,niṣe ni adinku ba iye awọn eeyan to lugbadi arun Covid 19 ni Naijiria.
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ́ arun lorileede Naijiria NCDC fi sita lalẹ ọjọ Ẹti, wọn ni eeyan 462 tuntun miran lo lugbadi arun naa.
Wọn fi ikede yi soju opo Twitter wọn.
Nibayi,awọn to ba arun naa lọ ni Naijiria ti wọ 879.
Eyan ti arun naa ti nawọ gan labẹ ayẹwo lapapọ ni Naijiria jẹ 43,151.
Onka awọn to to ti ri iwosan gba ti ara wọn ti ya lẹyin itọju bayi jẹ 19,565.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ti ṣe lọ ni :
FCT-93
Lagos-78
Plateau-64
Kaduna-54
Oyo-47
Ondo-32
Adamawa-23
Bauchi-19
Rivers-9
Ogun-9
Delta-9
Edo-7
Kano-6
Enugu-6
Nasarawa-5
Osun-1
Eeyan 481 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 878 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 42,681 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 19,270 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
FCT-96
Eko-89
Plateau-68
Ogun-49
Edo-44
Rivers-43
Oyo-25
Osun-23
Delta-15
Enugu-11
Kano-7
Kaduna-7
Bauchi-2
Bayelsa-1
Yobe-1
Èèyàn 5 kú, 404 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́rú
Eeyan 404 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
- Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà
- Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ (Toluige Olokoobi Babalola)
- Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀
- Ìpínlẹ̀ Oyo kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19
- Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀
Nibayii, eeyan 873 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 42,208 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 18,203 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-106
FCT-54
Rivers-48
Plateau-40
Edo-29
Enugu-21
Oyo-20
Kano-18
Ondo-15
Ogun-10
Ebonyi-9
Ekiti-8
Kaduna-6
Cross River-5
Kwara-4
Anambra-3
Delta-3
Imo-2
Nasarawa-2
Borno-1
Èèyàn 624 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Iṣẹ́gun
Eeyan 624 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
- Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà
- Akeredolu yan ọmọ Ilajẹ gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò ní Ondo
- Ìjọba àpapọ̀ ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jí owó ìlú kó, àwọn 1,400 ti wà nínú ẹ̀wọ̀n -Lai Mohammed
- Toke Makinwa ti sọ̀rọ̀; Amcon náà dá a padà fún un pé...
- Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC
Nibayii eeyan 868 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 41,804 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 18,203 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-212
Oyo-69
Niger-49
Kano-37
Osun-37
FCT-35
Plateau-34
Gombe-33
Edo-28
Enugu-28
Ebonyi-17
Delta-10
Katsina-9
Ogun-8
Rivers-7
Ondo-5
Kaduna-4
Nasarawa-2
Èèyàn 2 kú, 648 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àjé
Eeyan 648 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 860 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 41,180 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 18,203 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko -180
Plateau-148
FCT- 44
Ondo- 42
Kwara-38
Rivers-32
Oyo-29
Kaduna-21
Osun-20
Edo-17
Ogun-17
Ekiti-11
Kano-9
Benue-9
Delta-9
Abia-9
Niger-7
Gombe-3
Borno-1
Bauchi-1
Imo-1
Èèyàn 555 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Aiku
Eeyan 555 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 858 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 40,532 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 17,374 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-156
Kano-65
Ogun-57
Plateau-54
Oyo-53
Benue-43
FCT-30
Ondo-18
Kaduna-16
Akwa Ibom-13
Gombe-13
Rivers-12
Ekiti-9
Osun-8
Cross River-3
Borno-2
Edo-2
Bayelsa-1

Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC
Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta
Eeyan 438 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 856 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 39,977 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 16,948 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-123
Kaduna-50
Rivers-40
Edo-37
Adamawa-25
Oyo-20
Nasarawa-16
Osun-15
Enugu-15
FCT-14
Ekiti-13
Ondo-13
Ebonyi-11
Katsina-10
Abia-9
Delta-8
Kwara-4
Ogun-3
Cross River-3
Kano-3
Bauchi-3
Yobe-2
Sokoto-1
Niger-1
Èèyàn 591 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Ẹtì
Eeyan 591 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 845 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 39,539 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 16,559 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Èèyàn 20 kú, èèyàn 604 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́bọ
Eeyan mẹrinlelẹgbẹta ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Ajọ NCDC ni ipinlẹ ogun ni wọn ti ri awọn alekun awọn to laarun naa.
Bakan naa lo fi kun un pe eeyan ogun ni aarun naa tun ti pa.
Mibayii iye awọn to ti jalaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria ti di ẹgbẹrin ati mẹtalelọgbọn.
Apapọ iye awọn ti arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria ti din diẹ ni ẹgbẹrun mọkandinlogoji.
Ẹwẹ, ẹgbẹrun mẹrindinlogun ati mọkanlelọgọta lawọn eeyan to ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
- Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà
- Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà
- Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́! - Ìjọba àpapọ̀
- Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀
- Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù
Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú
Apapọ iye awọn to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria bayii ti di ẹgbẹrun mejidinlogoji ati ojilelọọdunrun o le mẹrin, 38,344 lẹyin ti eeyan ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹta, 543 kun wọn l'Ọjọru
Ajs to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ.
Bi atupalẹ afikun awọn to kun iye arun coronavirus ni Naijiria se lọ niyi
Eko-Ọgọsan, Abuja_mẹrindinlaadọrun, Kaduna mẹrindinlọgọta, Ondo-mẹtadinlogoji- Kwara- marundinlogoji, Ogun-19, Rivers-19, Kano-17, Ebonyi-16, Enugu-16, Delta-7, Bayelsa-4, Bauchi-3, Abia- 1
Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà
Eeyan Ọrinlelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC tun kede ni alẹ ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelogun oṣu keje pe ayẹwo tun fihan pẹlu arun coronavirus.
Ipinlẹ mọkanlelogun ni awọn eeyan naa ti jẹyọ.
Bakan naa ni ajọ NCDC tun fi kun un pe eeyan mẹrin miran ti padanu ẹmi wọn nipasẹ awọn aisan to peleke tori arun yii lagọ ara wọn.
Nibayii, apapọ iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o laarun naa ni Naijiria bayii ti di ẹgbẹrun mẹtadinlogoji ati mọkanlelẹgbẹrin, 37, 801.
Agbekalẹ awọn to laarun naa lati ipinlẹ de ipinlẹ niyii:
Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná
Olu ilu orilẹ-ede Naijiria, Abuja lo lewaju lori atẹ awọn ti ayẹwo fihan gẹgẹ bi ara awọn to kun iye arun coronavirus lọjọ Aje.
Ipinlẹ Eko lo tẹlee pẹlu ọgọrun eeyan ti ipinlẹ Plateau si ni mejilelaadọta.
Lapapọ eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹta ati meji ni ajọ NCDC tun kede pe o kun iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni arun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Aje, ogunjọ oṣu keje, ọdun 2020.
Pẹlu bo ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlogoji o le igba ati marundinlọgbọn, 37,227.
Ẹgbẹrun marundinlogun o le ọọdunrun ati mẹtalelọgbọn lo ti ri iwosan, ṣugbọn ẹgbẹrin o le ẹyọkan ẹmi lo ti baa rin.
Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà

Eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin lo tun kun iye awọn to ni aarun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ.
Ajọ NCDC tun ṣalaye pe o ti le ni ẹgbẹrun marundinlogun eeyan to ti ri iwosan lọwọ arun ọhun lorilẹ-ede Naijiria lọwọ bi a ṣe n sọrọ yii.
Bakan naa lo fi kun un pe ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o le mẹsan lawọn eeyan to ti jade laye nipasẹ arun yii lorilẹ-ede Naijiria.
Ajọ NCDC tun kede pe awọn ti ayẹwo tun ti fihan pe o ti larun naa ni ọjọ Aiku ni ipinlẹ si ipinlẹ niwọnyii.


















