BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Yinka Alaseyori ṣàlàyé ara rẹ̀ lórí fídíò tó ṣe nípa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
Ṣaaju ni Yinka ti sọ ninu fidio kan to gbe jade wi pe kawọn ọmọ Naijiria tẹsiwaju lati maa gbadura lori eto aabo to mẹhẹ.
Agbébọn jí àbúrò mínísítà fún ohun àmúṣagbára tẹ́lẹ̀, Adebayo Adelabu àti ìbejì rẹ̀ gbé lọ ní Ibadan: ohun tí a mọ̀ rèé
A gbọ pe akoko ti Olaide Busayo Adegoke John-Paul atawọn ibeji rẹ, Peter ati Paul nlọ si ile ẹkọ wọn ni isẹlẹ ijinigbe ọhun waye.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún mẹ́rin nínú afurasí márùn ún fún ìkọlù ìjọ Kátólíkì nílùú Owo, tí wọ́n ti pa èèyàn 41 lọ́dún 2022
Ikọlu naa to waye ni ọjọ karun un oṣu kẹfa ọdun 2022 ninu eyi ti olujọsin mọkanlelogoji ti jade laye ti ogoje miran si farapa.
Ta ni Kingsley Chinda tó kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lọ sí APC láti du ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Rivers?
Ninu lẹta kan ti Kingsley Chinda kọ sile ọhun lọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2026 yii amọ ti wọn ka ninu ile ọhun lana ọjọ keji, oṣu Kẹfa, ọdun 2026 lo ti fidi ọrọ naa lede.
Fídíò, Bàbá mi ló pàṣẹ fún mi lójú àlá pé kí n máa múra bí ọkùnrin – Funmilayo Elemure Ogunyemi, Duration 4,11
Arabinrin Funmilayọ ṣalaye pe lootọ eyi ko dun mọ awọn akẹgbẹ oun lọkunrin ti wọn n kọ irufẹ orin yii kan naa.
Mo kọ N500m tí wọ́n fi lọ̀ mi láti dènà Ajimobi nígbà tó fẹ́ di gómìnà, àmọ́ ó padà gbàgbé mi- Taiwo Otegbeye
Taiwo Otegbeye lo dupo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Action Alliance, ni 2011.
Fayose nílò àdúrà, ẹ ṣàánú rẹ̀ – Makinde da padà lẹ́yìn tí Fayose ní ó lè jẹ́ òun ló ṣagbátẹrù ìjínigbé Ogbomoso
Ninu atẹjade kan ti kọmiṣọna fun iroyin ipinlẹ Oyo, Dotun Oyelade fi lede lorukọ gomina Seyi Makinde, o ni iyalẹnu nla ni ẹsun ti Fayose fi kan Makinde jẹ.
Àwọn ilé ẹ̀kọ́ tilẹ̀kùn wọn pa l'Osun nítorí ìròyìn pé agbébọn wọ ìlú, Adeleke ní kò sí ohun tó jọ bẹ́ẹ̀
Adeleke ni awọn ọta ilu atawọn ọmọ ẹgbẹ alatako lo n gbe iroyin ẹlẹjẹ naa iri.
Aráàlú fárígá, àwọn olùwọ́de já géètì sẹkitéríàtì ìjọba, ìpè fún ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso káàkiri Nàìjíríà
Awọn eeyan naa ti wọn ko ara wọn lati fi aidunnu wọn han si bawọn eeyan naa ṣe wa ni akata awọn ajinigbe lati ọjọ kẹẹdogun oṣu Karun un ti kọja, bẹnu ẹtẹ lu bi ijọba ko ṣe tii ri wọn doola.
Ìjàmbá ọkọ̀ ló fa ikú òṣèré tíátà, 'Janmole' - Mr Latin
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere TAMPAN, Ọgbẹni Bolaji Amusan, tawọn eeyan mọ si Mr Latin lo fi iroyin iku naa lede loju opo Instagram rẹ.
Èyí làwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò ààrẹ ní 2027 tórúkọ wọn gbilẹ̀ jù
Awọn ẹgbẹ alatako torukọ wọn gbilẹ ju ni ADC, NDC ati PDP
Àwọn wo ló fẹ́ wú ère ẹlẹ́sẹ̀ ayò, Lionel Messi, àti pé kí ló fàá?
Ere giga naa to wa ni Kolkata, ni West Bengal ni wọn gbe kalẹ ninu oṣu Kẹwaa ti Messi rinrinajo 'GOAT' lọ sorilẹede ọhun.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Kókó ohun tó jẹyọ lásìkò àbẹ̀wò ìgbìmọ ìjọba àpapọ̀ sí Ogbomoso lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé
Igbimọ naa kọminu lori iṣẹlẹ ọhun, wọn si ṣeleri pe Aarẹ Bola Tinubu yoo sa gbogbo agbara rẹ lati doola gbogbo awọn ti wọn ji gbe.
Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún
Makinde sọ fún gbogbo eeyan to wa nibi ipade naa to waye ni Esinele pe kí wọn ma foya torí ìjọba n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe won doola awon t'awọn jàndùkú agbébọn ji gbe lọ.
Ẹgbẹ́ olùkọ́ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì l'Oyo lórí àwọn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, Tinubu kéde ìgbésẹ láti gba aṣógbó 1,000 síṣẹ́
Ṣaaju ni ẹgbẹ NUT ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo wi pe ki wọn ṣe ifẹhonuhan lati beere fun itusilẹ awọn tawọn janduku agbebọn ji gbe.
Seyi Makinde ni yóò ṣojú wa nínú ètò ìdìbò Ààrẹ ọdún 2027 – Ẹgbẹ́ òṣèlú APM
Ikede yii lo waye nibi eto idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa to waye ninu gbangan ọmọwe agba Theofilus Ogunlesi to wa ni adojuko ile iwosan UCH, nilu uIbadan.
Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti máa san ₦100,000 gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ
Wọn ni eyii jẹ ọkan lara awọn ọna lati mu aye dẹrun fun awọn oṣiṣẹ naa latari bi ọrọ aje Naijiria ṣe le koko lonii.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dáná sun ilé ẹkọ̀ tí akẹgbẹ́ wọn 16 ti kú
Lẹyin ti agbofinro fi ọrọ wa awọn olukọ ati ọpọ akẹkọọ lẹnuwo, ti wọn si wo ẹrọ CCTV to wa nibẹ ni wọn fidi rẹ mulẹ pe akẹkọọ mẹjọ kan lo pilẹ iṣẹlẹ naa ti wọn si sọ ina sile ẹkọ ọhun.
''Tí ìjọba bá lè gba ọmọ Yoruba láyè láti lo ìlànà ti ìbílẹ̀, ilẹ̀ wa yóò bọ́ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀mí''
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Obarisa Ilorin Afonja, Oba Omobolaji Adifakawo Agbomola, sọ pe awọn agbara ti Afọnja fi jagun si wa sibẹ, awọn si le lo o lati sẹgun ijinigbe ati ipaniyan ti ijọba ba gba awọn laye.
Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀ gbé ní Katsina
Ọgagun Rabe Abubakar to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun Naijiriala larin ọdun 2015 si ọdun 2017 ni wọn ji gbe lasiko ti wọn kọlu ọkọ rẹ lasiko to n rinrinajo lọ si ipinlẹ Katsina.
'A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso,' àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l'Oyo
Awọn olukọ naa bẹrẹ iwọde wọn lati agbegbe Iwo road niluu Ibadan ti wọn si gba Idi-ape, Gate titi de ọfiisi ijọba Ipinlẹ Oyo ni Agodi niluu ibadan.
Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé
Ṣaaju eto ayeye ọdun ọhun to waye lọjọ Ẹti, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Karun-un ti a wa yii, ni oniruuru awuyewuye ti n waye lori boya eto naa ko ni waye lọdun yii.
Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo
Ofin tuntun ọhun tun ke pe araalu lati fi to ijọba leti ti wọn ba kofiri ẹnikẹni to ba n ṣe nnkan naa ti wọn ti fofin de.
Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé
Awọn mọlẹbi oloogbe naa lo kede iroyin iku rẹ ninu atẹjade kan lọjọ Abamẹta.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin
Bi AI ṣe wulo lati mu iṣẹ ya kankan, bẹẹ naa ni awọn to mọ lilo rẹ nidakeji tun maa n lo o lati ya fidio eeyan tabi lo ohùn ẹnu ẹni ti wọn ba fẹ fi ṣe jamba fun.
Wo kókó ohun mọ́kànlá tí Tinubu fi ránṣẹ́ sọ́mọ Náíjíríà lórí ààbò àti ọrọ̀ ajé láti sàmì ọdún kẹta rẹ̀ nípò ààrẹ
Aarẹ Bola Tinubu ni yiyọ owo iranwọ ori epo, riro owo naira lagbara lọja agbaye ati gbigbe ogun ti aabo to mẹhẹ ti oun dawọle, ti so eso rere.
Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí
Ninu ọsẹ yii naa ni ọrọ fọnran ohun ti wọn fi AI gbe jade bọ sori ayelujara, nibi ti wọn ti fi ohùn ẹnu Tinubu sọ awọn ọrọ to n tako araalu, to si le da rugudu silẹ.
Iran ṣàlàyé ìdí abájọ tó fi ṣèkọlù sí ibùdó ológun Amẹrika
Ajọ IRGC ni oun ṣekọlu si ibudo naa lẹyin ti Amẹrika yin ado oloro si ẹkun guusu Iran.
Kí ni pàtàkì Òkúta Dúdú táwọn olùjọsìn máa ń fọwọ́ kan tàbí fẹnu kò ní Kaaba lásìkò Hajj?
Lọdọọdun ni ọpọ eeyan maa n ti ara wọn, koda wọn maa n tẹ awọn mii mọlẹ nibẹ lati ri pe awọn lanfaani lati fọwọ kan okuta naa.
Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe - Queen Mercy
Nigba to n sọrọ, Mercy ni oun kọ loun ran aṣọ naa, bi ko ṣe gbajumọ aranṣọ Toyin Lawani to jẹ ọga ileeṣẹ Tianah Empire.
Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam
Ọjọ Arafa ni ọjọ kẹsan oṣu Zul-Hijjah, ni onka oṣù ojú ọrun, tii se ọjọ Arafa.
Ìrọ́ ni pé PDP dara pọ̀ mọ́ APM l‘Oyo, ẹgbẹ́ wa tóbi ju ká dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú kankan lọ, àwa lá borí ìbò ààrẹ - Gbolarumi
BBC News Yoruba ba Amofin Azeem Gbolarumi sọrọ ni kete to wọle ibo abẹle PDP bii oludije gomina fẹgbẹ PDP nipinlẹ Oyo.
Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó
Ọlọpaa orukọ awọn ọlọpaa meji ti ọrọ naa kan lede gẹgẹ bii Kehinde ati Tobi lai mẹnuba orukọ wọn keji.











































































