BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìyàtọ̀ láàrin òfin owó orí tuntun tó wà lákọsílẹ̀ ìjọba àti èyí tílé aṣòfin buwọ́lù, ìdí táwọn aṣòfin fi figbe ta
Lopin ọsẹ to kọja ni ile aṣoju-ṣofin l'Abuja fi ẹda ofin naa sita, eyi ti Aarẹ Tinubu buwọlu.
Kí ló ń fa fàákája láàrin Wike àti akọ̀wé APC, tí Sẹ́nẹ́tọ̀ Basiru fi ní kí Wike kọ̀wé fipò mínísítà sílẹ̀? Àlàyé rèé
Sẹnẹtọ Basiru ni ọrọ ti Wike sọ tabuku oun ati ọfiisi oun gẹgẹ bii akọwe agba ẹgbẹ oṣelu APC, tori nnkan toun sọ wi pe gbogbo ọmọ ẹgbẹ igbimọ amuṣẹya NWC APC gbọdọ fawọn gomina to wa nipo lọwọ ni ọwọ to tọ si wọn.
Ṣé lóòótọ́ ni pé agbébọn làwọn èèyàn mẹ́fà táwọn ọmọ ogun mú ní ìpínlẹ̀ Edo pẹ̀lú ọkọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ Kwara?
Ninu osu Kejila, ọdun to kọja ni fọnran kan gba ori ayelujara eyi to ṣafihan awọn eeyan mẹfa kan ti wọn dọbalẹ, tawọn kan n beere nnkan lọwọ wọn.
Pásítọ̀ tó ní ayé yóò parẹ́ lọ́jọ́ Kérésì, kan ọkọ̀ ńlá, dèrò àhámọ́
Bi ọjọ Keresi ṣe n sunmọle, awọn Kristẹni kan tu yaaya lọ sibi ọkọ Ebo Noah, wọn fẹ wọle ki ẹkun omi ma baa pa wọn.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,54
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Fídíò, Ẹ bá mi rọ Ọba Ghandi kó má tún ìtàn Ògbórí Ẹlẹ́mọ̀ṣọ́ yà- Ẹda Onile Ola, Duration 3,57
Alagba Lere Paimo ni bi wọn ba fẹe ya itan Ogbomoso, o kunlẹ, dandan kọ ni ko jẹ Ogbori Elemọṣọ.
Àwọn ajínigbé tún jí èèyàn mẹjọ gbé ní Kwara
Iṣẹlẹ naa waye ni nnkan bi aago meje owurọ ni opopona Isanlu isin si Omu-Aran gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ.
Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, UN bu ẹnu àtẹ́ lu Amẹ́ríkà lórí ìkọlù sí Ààrẹ Venezuela
António Guterres nínú àtẹ̀jáde kan tó kà níbi ìpàdé pàjáwìrì tí àjọ náà pè lórí ìkọlù Amẹ́ríkà sí Venezuela sọ pé Trump kò tẹ̀lé òfin tó de àjọ àgbáyé lórí ìkọlù náà.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí pásítọ̀ Chris Okafor táwọn obìnrin fẹ̀sùn kan pé ó fipá báwọn lòpọ̀
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní pásítọ̀ náà, tó jẹ́ pásítọ̀ àgbà nínú ìjọ Mountain of Liberation and Miracles Ministries, ìpínlẹ̀ Eko máa kojú ìwádìí tó lágbára.
Lẹ́yìn oṣù mọ́kànlá, àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ padà sẹ́nu iṣẹ́ nípìnlẹ̀ Osun
Ti ẹ ko ba gbagbe pe, ọjọ Keje, osu Keji ọdun 2025 ni awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Osun ti lọ si ọfiisi gbẹyin latari ifanfa to n waye lori awọn alaga ijọba ibilẹ.
America fẹ́ẹ́ pa mi nínú ìkọlù, wọ́n ní Boko Haram ni mi-Sheikh Gumi
Gumi ni America n kede pe oun fẹ gba Naijiria la, lati ba awọn agbesunmọmi ja, ṣugbọn awọn gan-an ni agbesunmọmi.
Makinde ṣe àtúntò ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo, yọ Akọ̀wé ìjọba nípò
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti oludamọran gomina lori eto iroyin Sulaimon Olanrewaju fi sita; Makinde ti yọ akọwe ijọba ipinlẹ Oyo, Ọjọgbọn Olanike Kudirat Adeyemo atawọn mii nipo.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Wo ọjọ́ tí Ramadan yóò bẹ̀rẹ̀, ọjọ́ Àjíǹde, àti àwọn ọjọ́ ìsinmi tí ìjọba yóò kéde ní 2026
Yatọ si awọn eyi tijọba yoo kede awọn miiran wa to ṣe pe ikede kankan ko ni waye lori wọn sugbọn awọn eeyan yoo ṣami wọn tori pe ọjọ pataki ni fun wọn.
Mi ò fipò sílẹ̀ nítorí mo ṣe nǹkan tí kò tọ́, ṣùgbọ́n nítorí mo bọ̀wọ̀ fún ọ́fíìsì mi-Kemi Adeosun
Saaju ninu ọrọ Adeosun lọdun 2022, o ni ojoojumọ ni òun fi ń wa ẹkún mu fún oṣù mẹ́ta láì ṣe iṣẹ́ kankan.
Trump ni US yóò máa ṣàkóso Venezuela, ṣe àtúnṣe sí ẹ̀ka epo rọ̀bì
Ọjọ Satide, ọjọ kẹta oṣu kinni ni US kọlu Venezuela pẹlu awọn ọmọ ogun, tí ọwo si tẹ Maduro ati iyawo rẹ, Cilia Flores, ti wọn si ti gbe wọn kuro ni orilẹede naa.
Kà nípa bí o ṣe lè dènà àìsàn ọkàn, ìgbàgbé láti ẹni ọgbọ̀n ọdún
Bi awọn onimọ ijinlẹ ti wi, nigba ti eeyan ba wọ ọgbọn ọdun ni awọn ẹya ara bii egungun ati iṣan yoo bẹrẹ si fi awọn apẹẹrẹ agba han.
Kí ló ṣokùnfà tí kò fi sí ọyẹ́ lásìkò yìí?
Gẹ́gẹ́ bí ìṣe, tó bá fi máa di ìparí oṣù Kejìlá sí ìbẹ̀rẹ̀ oṣù Kìíní ọdún, ọyẹ́ ti máa ń mú gidigidi láwọn apá ibìkan káàkiri Nàìjíríà ṣùgbọ́n èyí kò rí bẹ́ẹ̀ lọ́dún yìí rárá.
Wo eré ìdárayá mẹ́rin tó lè mú ara rẹ jí pépé
Iwadii fidi rẹ mulẹ pe ṣiṣẹ idaraya loorekoore maa n ṣeranwọ fun eeyan ninu agọ ara, kii si jẹ ki ọkan eeyan daru.
Wo bí ètò ìsìnkú Allwell Ademola yóò ṣe lọ
Atẹjade isinku naa kede pe isin orin onigbagbọ yoo waye l'Ọjọbọ naa lati aago mẹrin irọlẹ titi di aago mẹfa.
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa obìnrin tó fẹ́sùn kàn pé wọ́n sọ iná sílé òun ní Ilorin nítorí pé òun ń ṣe ìṣẹ̀ṣe
Iṣẹlẹ jàmbá ina naa to jo gbogbo ile oniyara mẹjọ naa kanlẹ ṣẹlẹ lọjọ ọdún tuntun ọjọ Kiini, oṣu Kiini.
Báyìí ni ètò ìsìnkú Sina Ghami àti Latif Ayodele tó pàdánù ẹ̀mí wọn níbi ìjàmbá ọkọ̀ pẹ̀lú Anthony Joshua yóò ṣe lọ
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Oluseyi Babaseyi, sọ pe Ọgbẹni Adeniyi Mobolaji Kayode foju ba ile ẹjọ majisireeti to wa niluu Sagamu lonii ọjọ Ẹti ọjọ keji oṣu Kinni ọdun 2026 yii.
Fídíò, "Ẹní bá rokúròyín, mo wíi lórúkọ Olúwa, ọ́sán gangan làá gbọ̀'kú aró, òjijì làfọ̀n wọ̀ …"– Àgbà òṣèré tíátà, Lere Paimo wúre ọdún , Duration 1,20
Baba Ẹda ni nínú ọdún tuntun yìí, ojú wa ò ní rí ibi, ire la óò máa rí.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Orílẹ̀èdè Canada dá ọmọ Naijiria 366 padà sílé
Gẹgẹ bi akọsilẹ lati ẹka to n ri si eyi ni Canada, Canada Border Services Agency, (CBSA) ṣe wi, o tun ṣi ku eeyan 974 ti Canada fẹ da pada si Naijiria ti wọn ti wa.
Ìdí tí mo fí fẹ́ akọ̀wé ìjọba àpapọ̀, George Akume lẹ́yìn tí mo fi Ooni Ile Ife sílẹ̀ – Zaynab, Olorì Ooni Ogunwusi tẹ́lẹ̀ ṣàlàyé
Zaynab ti ọpọ mọ si Olori Wuraọla fẹ Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi fun oṣu mẹtadinlogun laarin oṣu kẹta ọdun 2016 si ọdun 2017.
Wo àwọn orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí kìí ṣe ayẹyẹ ọdún tuntun ní January 1
Nínú àwọn orílẹ̀ èdè tí wọn kìí ṣe ayẹyẹ ọdún tuntun ní January 1, BBC News Yorùbá ṣe àkójọ àwọn mẹ́wàá.
Ṣáká lára mi dá, mo ń lo Aspirin ju iye tí dókítà ní kí n máa lò lójúmọ́ - Ààrẹ Amẹ́ríkà, Donald Trump sọ̀rọ̀ lórí ìlera rẹ̀
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan tó ṣe nípa ìlera rẹ̀, Trump sọ fún iléeṣẹ́ ìròyìn The Wall Street Journal pé òun ṣe àyẹ̀wò CT scan nínú oṣù Kẹwàá lẹ́yìn tó ṣèṣì sọ fún àwọn akọ̀ròyìn pé òun ti ṣe àyẹ̀wò MRI scan.
Ìjọba Eko ṣí ojú òpó láti ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí tí èèyàn wọn há sábẹ́ ilé ìtajà tó jó lọ́jà Balogun
Àtẹ̀jáde tí àjọ tó ń mójútó ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Eko ìyẹn Lagos State Emergency Management Agency, LASEMA ṣe sọ, wọ́n ní àjà kẹrin ni iná náà ti dédé ṣẹ́yọ.
Èèyàn mẹ́fà kú lọ́jọ́ ọdún tuntun nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní márosẹ̀ Eko s'Ibadan
Ajọ FRSC to n ri si aabo loju popo, fidi ẹ mulẹ pe yatọ si awon to di oloogbe, eeyan meji mi-in tun farapa nibi ijamba to waye ni ikorita NASFAT naa.
Àwọn kókó tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ ìkínikúọdún tí Ààrẹ Tinubu fi ránṣẹ́ sáwọn ọmọ Nàìjíríà
Ninu ọrọ ikini ku ọdun rẹ si awọn ọmọ Naijiria, eyi to sọ laaarọ oni, ọjọ kin-in-ni, oṣu Kin-in-ni ọdun 2026 ni Tinubu ti kede bẹẹ.
Dúkìá ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù jóná, ẹ̀mí sùn níbi ìjàmbá iná méjì tó ṣẹlẹ̀ láàárín ọ̀sẹ̀ kan l'Eko
Lanaa ọjọ Iṣẹgun ti i ṣe ọgbọnjọ oṣu Kejila ọdun 2025 ni iroyin jade pe apa kan ọja Arena ni Oshodi n jona.







































































