Coronavirus in Nigeria: Èèyaǹ 135 ló ṣọ ṣẹ̀ṣẹ̀ kó àrùn Coronavirus ní Naijiria

Abẹrẹ Covid-19

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 29

Ninu atẹjade ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijria, NCDC, ṣẹṣẹ gbe jade loru Ọjọbọ, eeyan márùndínlógóje, 185, lo ṣẹṣẹ lugbadi Covid-19 ni Naijiria.

Bo tilẹ jẹ pe apapọ awọn to ti ri iwosan ti le ni 146,000, awọn ti arun naa ti mu ẹmi wọn lọ ti le diẹ ni ẹgbẹrun meji.

Atupalẹ iye awọn to ṣẹṣẹ lugbadi Covid-19 ni Naijiria ti NCDC gbe jade ree:

Lagos-41

Imo-20

Ogun-14

FCT-10

Kebbi-11

Rivers-10

Akwa Ibom-8

Plateau-4

Ebonyi-3

Kaduna-3

Kano-3

Osun-3

Oyo-2

Ekiti-1

Gombe-1

Nasarawa-1

Èèyàn mẹ́sàn án ni Coronavirus pa ní Naijiria láàrín wákàtí mẹ́rìnlélógún

Aworan ẹni to n gba abẹrẹ Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDC

Abajade ti ajọ NCDC fi lede loju opo Twitter rẹ loru mọju ti fi han pe eeyan mẹsan an lo ba arun Covid-19 lọ ni Naijiria.

Bakan naa ni ajọ ọhun tun kede eeyan mẹ́tàdínláàdọ́wàá, 187, to ṣẹṣẹ ko arun naa ni Naijiria.

Ṣugbọn ikede naa tun fi han pe ọọdunrun ati mẹtalelogun, 323, eeyan ri iwosan gba, ti wọn si ti pada sile wọn.

Iye awọn to ṣẹṣẹ ko arun Covid-19 ni Najiria ree ati ipinlẹ ti wọn ti wa.

Eko-42

Taraba-29

Edo-17

Abia-13

Rivers-11

Kaduna-10

Katsina-9

Oyo-9

Kwara-7

Plateau-7

Ondo-5

Bayelsa-4

Cross River-4

Ogun-4

Osun-4

Akwa Ibom-3

Borno-3

Nasarawa-3

NCDC

Oríṣun àwòrán, @NCDCgov

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede eeyan mọ́kàndínlọ́gọ́sàn án to ṣẹṣẹ ko arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Iṣẹgun.

Ṣugbọn ikede naa tun fi han pe eeyan meji jẹ Ọlọrunn jope nipasẹ arun naa, nigba ti ọọdunrun ati ogun eeyan ri iwosan gba, ti wọn si ti pada sile wọn.

Lẹnu ọjọ mẹta yii, iye awọn to n ko arun ọhun ti n dinku si ju ti atẹyinwa lọ.

Iye awọn to ṣẹṣẹ ko arun Covid-19 ni Najiria lọjọ Iṣẹgun ree ati ipinlẹ ti wọn ti wa.

Eko -47

Kaduna-21

Rivers-18

Akwa Ibom-14

FCT-11

Edo-10

Cross River-9

Ogun-9

Nasarawa-6

Ebonyi-5

Ekiti-5

Zamfara-5

Delta-4

Kano-4

Osun-4

Plateau-3

Abia-2

Gombe-1

Sokoto-1

Ìpínlẹ̀ Eko ló lékè nínú àwọn ìpínlẹ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus júlọ lọ́jọ́ Ajé

ncdc

Oríṣun àwòrán, @NCDCgov

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria ti gbe onka iye eeyan tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 jade lọjo Aje.

Gẹgẹ bii ohun ti wọn gbe jade koju opo Twitter wọn, eeyan òjìlènígba dín meji, 338, lo lugbadi arun naa.

Lẹnu ọjọ mẹta yi, iye awọn to n ko arun ọhun ti n dinku si ju ti atẹyinwa lọ.

Iye awọn to ko arun Covid-19 ni Najiria lọjọ Aje ree ati ipinlẹ ti wọn ti wa.

Eko -72

Kwara-28

Bauchi-19

Kaduna-19

Edo-17

Ogun-15

Nasarawa-13

Rivers-10

FCT-9

Ondo-8

Akwa Ibom-5

Gombe-5

Niger-5

Osun-5

Plateau-4

Oyo-3

Kano-1

Ondo ló lékè nínú ìpínlẹ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus júlọ ní Ọjọ́ Àbámẹ́ta

NURTW

Oríṣun àwòrán, TWITTER

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 205 mii lo lùgbàdì ààrùn Coronavirus ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹti.

Eeyan 2013 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 160,537 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti o ni arun Covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 144,714 lo ti gba iwosan ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ati ipinlẹ wọn.

Ondo-33

Lagos-25

FCT-22

Bauchi-21

Akwa Ibom-15

Kaduna-14

Katsina-13

Ogun-13

Rivers-11

Edo-8

Ekiti-4

Imo-4

Kano-3

Nasarawa-2

Niger-2

Èèyàn 399 tún ti lùgbàdì Covid-19 ní Nàijíríà ní Ọjọ́ Ẹtì

Awọn oṣiṣẹ eleto ilera

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 399 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹti.

Eeyan 2009 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 160,332 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti o ni arun covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 144,059 lo ti gba iwosan ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ati ipinlẹ wọn.

Lagos-101

Anambra-96

Edo-50

Abia-29

Imo-28

Ogun-19

Akwa Ibom-16

Kaduna-13

FCT-7

Bayelsa-6

Kano-6

Oyo-6

Delta-5

Rivers-5

Nasarawa-4

Ebonyi-3

Osun-3

Gombe-2

Èèyàn 287 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Adinku diẹ ba iye eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria lỌjọbọ.

Aworan iye awọn to lugbadi Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDC

Ninu atẹjade ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijria NCDC ti ṣe sọ, eeyan mẹjọ lo ku laarin Ọjọru si Ọjọbọ tawọn ọ̀rìnlénígba lé meje mii lugbadi arun naa.

Lọjọru yi kan naa ni ileeṣẹ to n mojuto ilera alabọde ni Naijiria fiwe sita lori iroyin to gbode pe abẹrẹ Astra-Zeneca to n ṣeku paayan lo wa nita.

Ninu ọrọ ti agbodegba ileeṣẹ yi fi sita, o ni Naijiria ko gba ẹda abẹrẹ naa to ni kọnunkọhọ ninu.

Pupọ awọn ipinlẹ lo ti n ri abẹrẹ gba ninu miliọnu mẹrin ti ijọba Naijria ri gba lọwọ ajọ COVAX to n ṣeto abẹrẹ yi lọfẹ.

Atupalẹ iye awọn to lugbadi Covid-19 ni Naijiria ti NCDC gbe jade ree:

Lagos-107

Kwara-26

Akwa Ibom-23

Bauchi-22

Ogun-21

Rivers-19

Kaduna-14

FCT-11

Abia-8

Edo-8

Ekiti-6

Kano-5

Gombe-4

Osun-4

Oyo-3

Plateau-3

Nasarawa-2

Delta-1

Aworan ẹni to n gba abẹrẹ Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDC

Eeyan 394 tuntun miran ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC gbe jade fun ọjọru nilẹ naa.

Ikede yi wa loju opo wọn ni Twitter.

Ipinlẹ Eko ko si ninu awọn ipinlẹ ti wọn gbe iroyin wọn jade ti Bauchi si le tente pẹlu eeyan marundinlọgrin.

Ni akọsilẹ, apapọ awn to ti lugbadi arun naa bayi ni Naijiria ti di 159,646 ti awọn ti arun naa pa si jẹ 1,993.

Atupalẹ bi nkan ti ṣe ri lawọn ipinlẹ to ku ree:

Bauchi-75

Lagos-36

Akwa Ibom-33

FCT-32

Nasarawa-29

Kaduna-26

Rivers-25

Ogun-22

Oyo-21

Edo-20

Taraba-18

Imo-17

Ondo-17

Borno-8

Plateau-7

Zamfara-4

Osun-3

Kano-1

Awọn oṣiṣẹ eleto ilera

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà lékun sí pẹlú 346

Awọn eeyan to padanu ẹmi wọn lati owo arun Covid-19 ni Naijiria ti di 1,988 lẹ́yin ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC gbe jade loju opo wọn.

Gẹgẹ bi iṣe wọn, ikede naa fun ti ọjọ Iṣẹgun ṣalaye iye awọn eeyan tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa.

Ohun ta ri nibẹ ni pe eeyan 346 tuntun lo ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria ti apapọ iye awọn to ti ni arun naa bayi si jẹ 159,252.

Atupalẹ awọn ipinlẹ ati bi wọn ti ṣe ni arun naa si leyi:

Lagos-86

Bauchi-64

Kaduna-26

Kwara-26

FCT-24

Rivers-23

Plateau-22

Ogun-16

Ebonyi-14

Bayelsa-12

Cross River-10

Edo-8

Akwa Ibom-5

Ekiti-3

Gombe-2

Kano-2

Osun-2

Delta-1

Abẹrẹ Covid-19

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC ti gbe onka iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ lugbadi Covid-19 jade lọjọ Aje.

Lori atẹ tuntun yi, ipinlẹ Eko ti wọn ko gbe onka awọn to lugbadi arun naa jade nibẹ lọjọ Aiku ti pada soke pẹlu eeyan mejilelgọrun.

Ijọba ati awọn eleto ilera ni Naijiria ti bẹrẹ si ni fawọn eeyan ni abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ti ireti si wa pe pupọ eeyan ni yoo ri gba ninu abẹrẹ naa.

Lapapọ awọn to ti lugbadi arun naa bayi, ikede ti NCDC fi sita loju opo Twitter sọ pe 158,906 ni wọn jẹ.

Eeyan mẹtala lo ku lọjọ Aje ti apapọ awọn taarun naa mu lọ si jẹ 1,982.

Atupalẹ bi nkan ṣe ri lawọn ipinlẹ kọọkan ree:

Lagos-102

Enugu-65

Edo-56

FCT-23

Ogun-20

Osun-18

Bayelsa-18

Rivers-15

Kaduna-14

Plateau-10

Oyo-8

Bauchi-7

Kano-5

Delta-4

Nasarawa-3

Niger-2

Ekiti-1

Aworan ayẹwo fun Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDC

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 269 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Awọn oṣiṣẹ eleto ilera

Oríṣun àwòrán, NCDC

Ipinlẹ Eko ko si lori atẹ awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti lugbadi Coronavirus eyi ti ajọ NCDC gbe jade fun ọjọ Aiku.

Enugu ni ipinlẹ to le tente pẹlu eeyan mejidinlọgọrin ti Bauchi si tẹle pẹlu eeyan mtadinlọgọrin.

Igba akọkọ kọ niyi ti ipinlẹ Eko ko ni si lori akasọ ṣugbọn ti wọn pada gbe iroyin awọn to lugbadi arun naa nibẹ jade ki il to ṣu.

Lapapọ, iye awọn to ti padanu mi wọn lọwọ Covid-19 ni Naijiria bayi jẹ 1,969 ti awọn 158,506 ni akọsilẹ wa pe wọn lugbadi arun naa.

Atupalẹ bi awọn eeyan ti ṣe lugbadi arun yi lawọn ipinlẹ Naijiria ree:

Enugu-78

Bauchi-37

Rivers-22

Imo-18

Ogun-16

FCT-15

Akwa Ibom-13

Kaduna-13

Kebbi-11

Kwara-9

Edo-7

Ekiti-6

Borno-5

Yobe-5

Kano-4

Nasarawa-3

Osun-3

Anambra-2

Plateau-2

Aworan ayẹwo fun Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDC

Èèyàn 70 péré ló kó coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko lọ́jọ́ Àbámẹ́ta

Aworan ayẹwo fun Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDC

Niṣe ni iye awọn to lugbadi arun Covid-19 dinku ni Naijiria lọjọ Abamẹta pẹlu ikede lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun iyẹn NCDC.

Lati iye eeyan 371 si 195 iyatọ eeyan 176 lo waye ninu onka tuntun ti ajọ naa fi soju opo Twitte wọn.

Awọn to lugbadi arun naa lapapọ di eeyan 158,237 ti awọn 137,645 si ti gba itọju tara wọn si ti ya.

Ni onka awọn to ba arun naa lọ, ajọ NCDC sọ soju opo wọn pe wọn jẹ eeyan 1,964 lapapọ ni Naijiria.

Atupalẹ bi awọn eeyan ṣe lugbadi arun naa ree lawọn ipinlẹ Naijiria.

Lagos-70

Kaduna-22

Abia-20

Edo-18

Kano-10

Akwa Ibom-9

Rivers-7

FCT-7

Borno-6

Bauchi-5

Osun-5

Oyo-5

Plateau-3

Ekiti-3

Niger-2

Ogun-2

Zamfara-1

Awọn oṣiṣẹ eleto ilera

Oríṣun àwòrán, NCDC

Èèyàn 371 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Abẹrẹ Covid-19

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria ti gbe onka iye eeyan tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 jade fọjọ Ẹti.

Ni oju opo wọn lori Twitter eeyan ọkanlelaadọrinlelọọdunrun,371, lo lugbadi arun naa.

Lẹnu ọjọ mẹta yi, iye awọn to n ko arun ọhun ṣebi ni dinku.

Aworan ayẹwo fun Covid-19

Oríṣun àwòrán, NCDCgov

Bakan naa ni orileede Naijria ti gba abẹrẹ ajẹsara ti awọn eeyan si ti bẹrẹ si ni gba a.

Lọjọ Ẹti ni ẹni akọkọ ti ṣe oṣiṣẹ ilera kan gba abẹrẹ naa ti awọn miran si ti n gba lẹyin rẹ.

Ipinlẹ Eko si le tente ninu awọn ibi ti ọwọja arun ọhun peleke si .

Awọn eeyan 158,042 ni wọn ti lugbadi Covid-19 bayii ti awọn 137,025 si ti gba iwosan lẹyin itọju.

Iye awọn to ku jẹ 1,954 lapapọ.

Awọn oṣiṣẹ eleto ilera to n gba abẹrẹ Covid-19

Oríṣun àwòrán, Reuters

Iye awọn to ko arun Covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.

Rivers-54

Anambra-31

Ebonyi-23

Imo-23

Kwara-22

Kano-20

Taraba-17

Akwa Ibom-16

FCT-15

Abia-13

Kaduna-13

Osun-5

Edo-4

Oyo-4

Kebbi-3

Ogun-3

Ekiti-2

Nasarawa-1

Zamfara-1

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 708 mii lo ṣẹṣẹ lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà.

Eeyan 1,951 lo ti ba ajakalẹ aarun Coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 157,671 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun Covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 136,335 lo ti gba iwosan ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.

Adamawa-180

Lagos-141

Ondo-60

Anambra-54

Rivers-41

Taraba-33

Edo-30

Abia-22

Kaduna-22

FCT-21

Akwa Ibom-20

Kano-20

Plateau-11

Ekiti-10

Kebbi-10

Nasarawa-10

Bayelsa-7

Ogun-5

Osun-5

Oyo-5

Gombe-1

Èèyàn 479 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 479 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Aje.

Eeyan 1,923 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 156,496 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti o ni arun covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 134,551 lo ti gba iwosan ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ati ipinlẹ wọn.

Lagos-153

Enugu-75

Rivers-50

FCT-40

Kaduna-18

Ebonyi-17

Plateau-17

Edo-17

Borno-16

Oyo-12

Kano-11

Abia-10

Cross River-10

Taraba-9

Nasarawa-7

Bauchi-4

Bayelsa-3

Delta-3

Ekiti-2

Niger-2

Ogun-2

Akwa Ibom-1

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 360 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Aje.

Eeyan 1,915 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 156,017 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 133,904 lo ti gba iwosan ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.

Eko-120

Edo-38

Kaduna-25

FCT-23

Imo-23

Delta-19

Akwa Ibom-17

Plateau-17

Rivers-16

Nasarawa-15

Kwara-13

Oyo-9

Ogun-8

Bauchi-4

Osun-4

Kano-3

Kebbi-3

Niger-2

Katsina-1

Èèyàn 240 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Nigeria

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 240 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹtì.

Eeyan 1,907 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 155,657 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 133,768 lo ti gbadun ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.

Anambra-85

Lagos-82

Osun-17

Ogun-10

Kwara-9

FCT-8

Kano-7

Abia-6

Borno-4

Edo-2

Bayelsa-2

Kaduna-2

Rivers-1

Èèyàn 341 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 341 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹtì.

Eeyan 1,905 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 155,417 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ, awọn 133,256 lo ti gbadun ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.

Eko-96

Rivers-41

Kaduna-33

Edo-21

Osun-20

Akwa Ibom-17

FCT-17

Ondo-15

Gombe-11

Kano-11

Imo-10

Ekiti-9

Kebbi-9

Kwara-8

Oyo-8

Borno-6

Enugu-3

Plateau-3

Delta-1

Niger-1

Ogun-1

Èèyàn 600 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 600 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹtì.

Eeyan 1,902 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.

Lapapọ, eeyan 155,076 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.

Amọ awọn 132,544 lo ti gbadun ninu wọn.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii.

Eko -169

Taraba-92

Ogun-65

Cross River-57

FCT-38

Rivers-28

Kwara-26

Akwa Ibom-25

Osun-21

Plateau-12

Borno-9

Gombe-9

Abia-8

Ebonyi-8

Ekiti-7

Kano-7

Delta-6

Oyo-6

Bauchi-3

Nasarawa-3

Sokoto-1

Èèyàn 875 míì ti kúrò nílé ìwòsàn, àmọ́ Coro tún ti gbẹ̀mí èèyàn mẹ́jọ o ní Nàìjíríà

Covid-19 tun ṣekú pa èèyàn mẹjọ l'Ọjọru, ọjọ kẹrinlelogun oṣu keji ọdun 2021.

Amọ ẹgbẹrin eeyan ati marunlelaadọrin lo fi ile iwosan silẹ ni Ọjọru bakan naa lẹyin ti wọn ti gbadun tan.

Eeyan 1,885 ni arun coronavirus ti ṣeku pa bayii ni Naijiria, nigba ti eeyan 130,818 ti jajabọ lọwọ arun naa.

Pẹlu iye awọn ọtalelẹgbẹta eeyan din marun tuntun to karun ọhun l'Ọjọru, o ti pe 153,842 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.

Ipinlẹ Eko lo tun lewaju pẹlu oji le lugba eeyan to lugbadi covid-19 ni Ọjọru.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọru niyii.

Lagos-240

Ogun-88

Rivers-56

FCT-51

Kaduna-43

Kano-25

Plateau-21

Taraba-19

Edo-17

Abia15

Delta-13

Nasarawa-11

Akwa Ibom-10

Kwara-10

Oyo-10

Kebbi-9

Borno-5

Bayelsa-4

Gombe-4

Ekiti-2

Osun-2

153,842

Èèyàn 170 ló kó coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko nìkan lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan aadọsan miran lo ko arun coronavirus nipinlẹ Eko nikan lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ọdun 2021.

Ajọ naa tun ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ẹẹdẹgbẹta eeyan ati mọkanlelaadọrin lo lugbadi arun naa kaakiri Naijiria lọjọ Iṣẹgun.

Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 153,187 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.

Àkọlé fídíò, 'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn'

Awọn 129,943 si ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan 1,874 ti jẹ Ọlọrun nipe.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria lọjọ Iṣẹgun niyii.

Lagos-170

Ogun-65

FCT-45

Kwara-34

Abia-32

Enugu-32

Kano-25

Oyo-22

Ondo-21

Rivers-19

Kaduna-19

Benue-18

Bayelsa-12

Kebbi-12

Nasarawa-11

Akwa Ibom-9

Delta-8

Ekiti-6

Niger-5

Bauchi-3

Imo-3

129,300 ló ti jàjà bọ́ lọ́wọ́ Covid-19 ní orílẹ́èdè Nàìjíríà

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorileede Naijiria NCDC ti kede pe eeyan 129,300 lo ti ri iwosan lọwọ arun coronavirus bayii.

Ṣugbọn eeyan 1,862 ni o ti ba arun lọ lorilẹede Naijiria lati igba ti ajakalẹ arun ọhun ti bẹ silẹ.

Ojilelẹẹdẹgbẹta eeyan le meji lo tun larun Covid-19 ni Naijiria lọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu keji ọdun 2021.

Eeyan 152,616 lapapọ ni ajọ NCDC sọ pe o lo ti ni arun coronavirus kaakiri orilẹede Naijiria.

Ipinlẹ Eko lo si n lewaju iwaju ninu awọn ipinlẹ ti arun naa ti pọju.

Eeyan mọkandinlọgọrun lo tun lugbadi covid-19 l'Eko lọjọ Aje.

Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria lọjọ Aje niyii.

Lagos-99

Kwara-91

Ebonyi-48

Ogun-44

Kaduna-42

Oyo-33

Ondo-25

FCT-24

Kebbi-23

Osun-20

Ekiti-17

Nasarawa-12

Imo-11

Delta-10

Gombe-9

Kano-8

Katsina-7

Rivers-7

Edo-5

Plateau-4

Bauchi-3

Covid-19 gbẹ̀mí èèyàn mẹ́jọ lọ́jọ́ Àìkú ní orílẹ́èdè Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 521 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ́ Aiku.

Ajọ naa ni eeyan mẹjọ lo tun ti gbẹmi mi nipasẹ arun naa bayii.

Ipinlẹ Eko lo si lewaju nibi ti eniyan 166 ti lugbadi arun ọhun, nigba ti eeyan mejilelaadọta larun naa nipinlẹ Ogun.

Lapapọ bayii, eeyan 152,074 ni akọsilẹ ajọ NCDC fihan pe wọn ti ko arun covid-19 ni Naijiria.

Skip X post, 1
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 1

Amọ eeyan to din diẹ ni ẹgbẹrun lọna aadoje(128,619) lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti lọ si ile wọn.

Apapọ awọn ti arun ọhun din diẹ ni ẹgbẹrun meji eeyan(1,839).

Akọsilẹ awọn ipinlẹ to nii covid-19 lọjọ Aiku re e:

Lagos-166

Ogun-52

Rivers-47

Adamawa-37

Ebonyi-37

Akwa Ibom-25

Osun-21

Bayelsa-18

Kaduna-17

Oyo-16

FCT-15

Ekiti-14

Kano-12

Edo-12

Borno-9

Yobe-8

Ondo-6

Nasarawa-4

Bauchi-2

Kwara-3

Coronavirus ti ṣekúpa èèyàn 1,831 ní Nàìjíríà báyìí - NCDC

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria fun ọjọ Abamẹta, ogunjọ oṣu keji ọdun 2021 jade.

Ninu ohun ti ajọ NCDC gbe jade loju opo ẹyẹnkọrin Twitter wọn, eeyan 645 lo tun kun awọn to lugbadi aarun yi.

Ipinlẹ Eko si lo lewaju nibi ti ojilelugba eeyan le meji ti ko arun ọhun lọjọ Abamẹta.

Ipinlẹ Ogun lo sikeji pẹlu eeyan mejilelaadọrin, Abuja wa ni ipo kẹta pẹlu aadọta eeyan.

Mẹrinlelogun lo larun naa lati ipinlẹ Osun, mẹtadinlogun nipinlẹ Oyo, mọkanla lati Ekiti nigba ti mọkanla tun lugbadi arun naa lati ipinlẹ Ondo.

Lagos-282

Ogun-72

FCT-50

Kaduna-33

Osun-24

Imo-23

Abia-21

Borno-18

Oyo-17

Edo-15

Nasarawa-15

Taraba-14

Ekiti-11

Ondo-11

Plateau-11

Kano-10

Rivers-7

Delta-5

Bauchi-3

Jigawa-3

Nibayii, eeyan 151,553 lo ti larun covid-19 ni Naijiria, 128,005 ninu wọn si ti jajabọ, amọ 1,831 eeyan lo ti ba arun naa lọ.

A ti rí ẹ̀yà Coronavirus tuntun ní Nàìjíríà- NCDC

Ajọ NCDC ti kede loju opo twitter wọn pe wọn ti ri ọkan lara ẹya aajakalẹ arun Coronavirus ni Naijiria bayii.

Wọn pe orukọ rẹ ni: ẹ̀yà SARS-CoV-2 ní Nàìjíríà.

Ajọ naa kede pe ki awọn eeyan ṣọra ṣe ṣugbọn ki wọn ma jaya ju nitori ẹjẹ riru.

Wọn ni iwadii to jinlẹ ti bẹrẹ bayii ki wọn le mọ igbese to kanlati mojutoo.

Skip X post, 2
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 2

Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó

Èèyàn 627 ni COVID-19 ti pa ní Nàìjíríà láàrín oṣù Dìsẹ́mbà sí àsìkò yìí, 16 ló kú l'Ọ́jọ́bọ̀ nìkan

Ààrùn COVID-19 tún gba ẹ̀mí èèyàn 16 ní Nàìjíríà, ènìyan 877 míràn sì kún iye àwọn tó láàrùn náà

Eeyan mẹrindinlogun ni COVID-19 tun ṣekupa lorilẹede Naijiria lọjọbọ; pẹlu bi iku to n tipasẹ arun naa wa ṣe n peleke sii lorilẹede Naijiria.

Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe sọ loju opo ẹyẹ nkọrin Twitter rẹ, ẹgbẹrun kan o le ẹgbẹrin ati mẹta, 1,803 lawọn ti arun naa ti ran jade laye lorilẹede Naijiria.

Eyi fihan pe laarin ọjọ kini oṣu kejila ọdun 2020 si asiko ti a wayi, eeyan okoolelẹgbẹta o le meje, 627 larun naa ti pa lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC tun jẹ ko di mimọ pe eeyan ọrinlelẹgbẹrin o din mẹta, 877 lo tun ko arun naa lọjọbọ.

Nibayii iye awọn to ni arun naa jẹ ẹgbẹrun lọna aadọja ati ojilelugba o le mẹfa, 150, 246 ninu eyi ti awọn ẹgbẹerun lọna ọgọfa o le mẹfa ati irinwo o le mẹtadinlogun, 126, 417 ti ri iwosan.

Lagos-273

Kaduna-87

Rivers-58

Akwa Ibom-47

Ebonyi-47

Edo-46

Ogun-46

Abia-34

Imo-34

Kano-34

Oyo-26

Osun-22

Gombe-20

Ekiti-19

Cross River-15

FCT-15

Plateau-11

Enugu-9

Kebbi-8

Borno-7

Niger-6

Bayelsa-5

Nasarawa-4

Kwara-2

Katsina-1

Sokoto-1

Láàrín ọjọ́ Ìṣẹ́gun sí ọjọ́rú, èèyàn 10 míràn ni COVID-19 tún pa ní Nàìjíríà

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria fun Ọjọru, ọjọ kẹtadinlogun oṣu keji jade.

Ninu ohun ti ajọ NCDC gbe jade loju opo ẹyẹnkọrin Twitter wọn, eeyan 869 lo tun kun awọn to lugbadi aarun yi.

Ipinlẹ Eko lo tun pada sipo iwaju lori rẹ lọtẹ yii lẹyin ọjọ diẹ ti o ti fi wa silẹ lori atẹ ọwọja arun COVID-19 ti ajọ naa maa n gbe jade lojumọ pẹlu okoolelugba o le mẹsan an eeyan to tun nii.

Ipinlẹ Rivers tẹle pẹlu 79 ti Taraba Oyo ati Ogun si tẹle pẹlu 73, 66, ati 66 ni ṣisẹ n tẹle

Lagos-229

Rivers-79

Taraba-73

Oyo-66

Ogun-60

FCT-58

Plateau-56

Kwara-38

Ondo-38

Osun-24

Kano-22

Nasarawa-21

Abia-19

Edo-19

Akwa Ibom-19

Cross River-10

Delta-9

Benue-8

Ekiti-6

Borno-6

Katsina-4

Bauchi-3

Bayelsa-1

Zamfara-1

Lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, COVID-19 tún gbẹ̀mí èèyàn 16 míràn ní Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe aarun COVID-19 tun ti ran eeyan mẹrindinlogun lọ sọrun lọjọ Iṣẹgun lorilẹede Naijiria.

Bakan naa ni ajọ tun ṣalaye pe eeyan okoolelẹẹdẹgbẹta (520) lo tun ko aarun naa ninu ikede to fi sita lọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2021.

NCDC sọ pe ipinlẹ Ondo lo ṣiwaju pẹlu ọgọfa eeyan tuntun to ko aarun naa.

Awọn ipinlẹ mii to nii arun naa niwọnyii:

Anambra-344

Oyo-172

FCT-148

Benue-107

Rivers-95

Ogun-59

Ondo-56

Ebonyi-53

Kaduna-52

Plateau-46

Kwara-36

Enugu-30

Akwa Ibom-26

Osun-22

Edo-20

Abia-17

Kano-16

Borno-15

Cross River-10

Delta-8

Gombe-8

Imo-7

Ekiti-5

Sokoto-4

Jigawa-3

Bayelsa-3

Nasarawa-3

Zamfara-3

Lọ́jọ́ Aje, ààrùn COVID-19 pa èèyàn mẹ́jọ ní Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 574 lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ́ Aje.

aj naa ni eeyan mẹjọ lo tun ti gbẹmi mi nipasẹ arun naa bayii.

Ipinlẹ Kwara ni eniyan 98 to lugbadi ọhun, nigba ti ilu Eko naa ni akọsilẹ eeyan 81 to ni arun ọhun.

Akọsilẹ awọn ipinlẹ to nii re e:

Kwara- 98

Lagos- 81

Edo- 59

Ondo- 44

FCT- 41

Kano- 34

Ogun- 33

Kaduna- 29

Osun- 28

Enugu- 23

Rivers- 18

Delta-16

Akwa Ibom-15

Bauchi-12

Imo-10

Borno-8

Niger-8

Kebbi-7

Nasarawa-5

Gombe-3

Ekiti-2

Lọwọyii apapọ iye awọn to ti ko aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹrun mẹrindinlaadọjọ o le okoolelẹẹdẹgbẹrun ati mẹjọ, 146, 928

Ẹgbẹrun mẹtalelọgọfa ati mẹsan, 123, 009 eeyan lo ti riwosan.

Lọ́jọ́ Valentine, ààrùn COVID-19 pa èèyàn márùn ún ní Nàìjíríà

Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe aarun COVID-19 tun ti ran eeyan marun un lọ sọrun lọjọ Valentine lorilẹede Naijiria.

Bakan naa ni ajọ tun ṣalaye pe eeyan okoolelẹẹdẹgbẹta (520) lo tun ko aarun naa ninu ikede to fi sita lọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2021.

NCDC sọ pe ipinlẹ Ondo lo ṣiwaju pẹlu ọgọfa eeyan tuntun to ko aarun naa.

Awọn ipinlẹ mii to nii arun naa niwọnyii:

Ondo-120

Borno-41

Ebonyi-37

Benue-33

Plateau-30

FCT-29

Nasarawa-25

Ogun-25

Edo-24

Osun-24

Katsina-22

Kaduna-21

Niger-20

Kwara-14

Ekiti-13

Yobe-10

Oyo-4

Bayelsa-1

Jigawa-1

Lọwọyii apapọ iye awọn to ti ko aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹrun mẹrindinlaadọjọ o le mẹrinlelọgọsan, 146, 184

Ẹgbẹrun lọna ọgọfa ati ojilelẹgbẹrin o din meji (120, 838) eeyan lo ti riwosan

Ààrùn COVID-19 gba ẹ̀mí èèyàn 13 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Sátidé

Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe eeyan mẹtala miran ni aarun COVID-19 tun ti ran lọ sọrun lọjọ kan ṣoṣo lorilẹede Naijiria.

Bakan naa ni ajọ ọhun fi kun un pe ni ipinlẹ Eko nikan ṣoṣo, eeyan okoolelọọdunrun o din ẹyọkan, (319) lo tun ti kagbako aisan Covid-19.

Wọn si tun kede rẹ pe awọn ẹgbẹrun kan o le ogoje ati mẹta (1,143) lo tun lugbadi aarun naa lọjọ Ababmẹta ọjọ kẹtala oṣu keji ọdun 2021 ni Nàìjíríà lọ́jọ́bọ̀.

Lẹyin ipinlẹ Eko ni ilu Abuja naa ni akọsilẹ eeyan mẹtadinlọgọjọ, (157) to ni arun ọhun. Awọn ipinlẹ mii to nii ni:

Lagos-319

FCT-157

Kwara-90

Oyo-74

Enugu-72

Nasarawa-69

Imo-58

Osun-51

Gombe-49

Kaduna-31

Edo-23

Katsina-23

Kebbi-23

Ogun-22

Kano-19

Rivers-19

Ebonyi-18

Plateau-14

Delta-7

Ekiti-5

Lapapọ bayii, eeyan 145, 664 ni akọsilẹ Ajọ NCDC fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria ti awọn 120, 399 ti gba itusilẹ amọ eeyan 1,747 lo ti gba tibi aisan yii ku.

Ènìyan 1005 ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria l'Ọjọ́ Ẹtì

Àjọ NCDC ti kede pe awọn eeyan 1005 lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ́ Ẹti.

Ipinlẹ Eko ni eniyan 204 to lugbadi ọhun, nigba ti ilu Abuja naa ni akọsilẹ eeyan 75 to ni arun ọ́hun.

Akọsilẹ awọn ipinlẹ to nii re e:

Lagos-204

Kwara-155

Oyo-124

Plateau-80

FCT-75

Edo-56

Osun-48

Ondo-41

Kaduna-40

Rivers-40

Taraba-35

Borno-32

Ekiti-21

Ogun-20

Kano-14

Bayelsa-8

Delta-7

Bauchi-3

Jigawa-2

'Aláìsàn 263 tán yányán ló kó o látara Covid ní Eko nínú èèyàn 938 tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì rẹ̀ ní Nàìjíríà'

Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe ni ipinlẹ Eko nikan ṣoṣo, eeyan 236 lo kagbako aisan Covid-19 ti wọn si tun kede pe awọn 938 lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà lọ́jọ́bọ̀.

Lẹyin ipinlẹ Eko ni ilu Abuja naa ni akọsilẹ eeyan 123 to ni arun ọ́hun. Awọn ipinlẹ mii to nii ni:

Plateau-92

Benue-63

Katsina-53

Oyo-50

Osun-45

Kaduna-43

Edo-33

Ogun-31

Ebonyi-31

Akwa Ibom-30

Kano-26

Gombe-18

Bauchi-16

Delta-12

Imo-11

Cross River-10

Rivers-10

Niger-5

Lapapọ bayii, eeyan 143,516 ni akọsilẹ Ajọ NCDC fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria ti awọn 118,012 ti gba itusilẹ amọ eeyan 1,710 lo ti gba tibi aisan yii ku.

Àjọ tó n gbógun ti àjàkalẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà, NCDC tí kéde pé òun ti ṣe ìwé ìtọ́ni tí àwọn tó bá ni ààrùn covid-19 le lò láti ṣe ìtọ́jú ara wọn nínú ilé.

Lójú òpó twitter àjọ náà ló gbe sí lọ́jọ́ Iṣẹ́gun pé àwọn ti ṣe ìwé ìléwọ́ tí yóò ràn àwọn tó bá ni ààrùn Covid-19 ti ko lágbára púpọ̀ láti le ṣe ìtọ́jú ara wọn nínú ilé.

Nínú ìwé náà ni àkorí mẹ́ta:

*Ọ̀nà láti ṣe ìtọ́ju ara ẹni nínú ilé

* Ọ̀nà láti dènà ààrùn náà lẹ́ẹ̀kejì

* Ọ̀nà láti mọjú tó ààrùn náà tó bá ti n fi àwọn àmì kan hàn

Tọ ojú ìlà yìí láti kaàwọn ìlànà náà kí o lé mọ bi ọ ṣe le ṣe ìtọ́jú ààrùn covid-19 ninu ilé.

Ẹ̀wẹ̀ àjọ náà tún kéde pé ènìyàn 1,056 lo tun lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà lọ́ja ìṣẹ́gun lòdì sí ènìyàn 643 tó jẹyọ lọjọ́ ajé.

Lagos-214

Osun-120

FCT-116

Plateau-88

Ebonyi-75

Kwara-73

Gombe-70

Ondo-57

Rivers-47

Akwa Ibom-38

Edo-25

Oyo-23

Kano-22

Delta-19

Katsina-18

Borno-16

Nasarawa-13

Ekiti-8

Ogun-8

Bauchi-4

Benue-1

Jigawa-1

Ìpínlẹ̀ mẹ́jìlélógún ni àwọn tó ni ààrùn náà ti jẹyọ.

Ní báyìí, ènìyàn 115,755 ló ti jàjàba lọ́wọ́ ààrùn covid-19 nígbà ti ènìyàn 1,694 ti báarìn.

Ìpínlẹ̀ 19 ni ọwọ́jà coronavirus dé ní Nàìjíríà nínú àtẹjáde NCDC lọ́jọ́ Ajé

Àjọ NCDC ti kilọ pé, ààrùn Covid-19 kò tíì tán nílẹ̀, ọwájà rẹ̀ sí n takálé, ta ká oko títí di àsìkò yìí.

Lásìkò tí ọgá àgbà àjọ náà Chikwe Ihekweazu ń sọ̀rọ̀ níbi ètò ìjábọ̀ ojojúmọ́ ti ìgbìmọ̀ PTF máa sẹ, pé ó ṣe pàtàkì láti jìnà réré síbi ayẹyẹ ti èrò bá pọ̀ sí kí wọ́n sì má fọwọ́ déedé.

Ẹ̀wẹ̀, nínú àtẹ̀jáde olójoojúmọ́ lójú òpó twitter NCDC ni wọ́n ti kéde kéde pé ènìyàn 643 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn covid-19 nínú èsì àyẹ̀wò tó jáde lọ́jọ́ ajé.

Àkọlé fídíò, Wo ìgbé àyé ìyá àti ọmọbìnrin tó ń fi iṣẹ́ aṣẹ́wó jẹun

Oyo-88

Lagos-86

Rivers-55

Edo-54

Akwa Ibom-53

Adamawa-52

Plateau-45

Kaduna-41

FCT-34

Kwara-27

Benue-20

Kano-19

Delta-18

Nasarawa-16

Niger-15

Bayelsa-11

Borno-5

Bauchi-2

Sokoto-2

Ìpínlẹ̀ Oyo ló dúró lókè tẹéńté lórí tábílì lọ́tl yìí nígbà ti Eko wà ni ipò kẹta.

Gẹ́gẹ́ bi NCDC se sọ, àwọn ènìyàn 744 lo gba ìtúsílẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Eko, 100 nípìnlẹ̀ Rivers, 78 ní ìpínlẹ̀ Plateau, 72 ní Kaduna nígbà tí wọ́n tú ènìyàn 2 sílẹ̀ ni Benue..

Ní báyìí ènìyàn 14,391 ló ti ni ààrùn covid-19 ni Nàìjíríà nígbà tí 114,635 gba ìtúsílẹ̀ nígbà tí ènìyàn 1,673 ti bá ààrùn covid-19 lọ.

Ìpínlẹ̀ ogún ni ọwọ́jà coronavirus dé ní Nàìjíríà nínú àtẹjáde NCDC lọ́ja Ajé

Láti bí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn báyìí ni ọwọ́jà ààrùn coronavirus ti n peléke sii, sùgbọ́n àbájáde èsì àyẹwò olójoojúmọ́ ti àjọ NCDC máa ń gbé jáde lójoojúmọ́ fi hàn pé èsì àyẹ̀wò ọja Aiku ṣẹ́ pẹ́rẹ́.

Ní ọjọ́ Aiku àjọ NCDC fi léde pé, ènìyàn méjì lé lẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta ló ni ààrùn náà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni àwọn ìpínlẹ̀ ti èsì tí jáde.

Ipò kẹsan ni ìpínlẹ̀ Eko tó máa n sábà lé wájú wà lónìí nígbà ti ìpińlẹ̀ Ondo, Kwara àti Rivers gbégbá orókè nínú àwọn ìpińlẹ̀ to ni ààrùn náà.

Àlàyé ipò ti ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kàn tó jẹyọ wà rèé:

Ondo-90

Kwara-89

Rivers-53

Borno-45

Gombe-32

FCT-28

Imo-26

Ogun-25

Lagos-22

Kaduna-14

Kano-14

Edo-13

Osun-11

Cross River-10

Yobe-9

Ekiti-7

Kebbi-6

Nasarawa-6

Oyo-5

Jigawa-1

Ní báyìí apapọ ènìyàn tó ti lùgbàdì ààrùn coronavirus ni Nàìjíríà ni 139,748, ènìyàn 113,525 lo ti san ti wọn sì ti padà sílé wọn nígbà ti ènìyàn 1,667 ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn.

Lánàá òde yìí ni àjọ NCDC fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, ènìyàn mílíọ̀nù kan ni òun ti ṣe ayẹwò fún ni Nàìjíríà láti bi ọdún kan sẹ́yìn.

Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 1,588 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà.

Àjọ tó n gbógun ti ààrùn coronavirus ní Nàìjíríà (NCDC) tí kéde lóru mójúmọ́ pé ènìyàn 1,588 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn coronavirus ni Nàìjíríà.

Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe gbé e sójú òpó twitter wọn pé, ìpínlẹ̀ Eko ló ṣì tún léwájú nínú àwọn ìpińlẹ̀ tó ni ààrùn náà jùlọ pẹ̀lú ènìyàn 535 tó jẹ́ iye kan náà gẹ́gẹ́ bíi ìròyìn tí ìjẹta, Anambra ló tẹ̀lé pẹ̀lú ènìyàn 218, Oyo jẹ́ 155, Abuja 150.

Kano-124, Gombe-60, Kaduna-49, Ebonyi-48, Plateau 46, Akwa Ibom-39, Niger-37, Edo-33, Katsina-23, Rivers-18, Taraba-15, Nasarawa-14, Ogun-11, Delta-9, Ekiti-2, Jigawa-2 ní ọjọ́ Àbámẹ́ta.

Ní báyìí àpapọ̀ àwọn tó ti ní ààrùn coronavirus ni Nàìjírí ti jẹ́ 139,242, ènìyàn 112,557 ti rí ìwòsan nígbà tí ènìyàn 1,647 tí bá ìṣẹ̀lẹ̀ ààrùn Covid-19 lọ.

Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 1,340 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.

Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 1,340 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.

Olu ile orilẹede Naijiria, Abuja to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;

Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:

FCT-320

Lagos-275

Rivers-117

Oyo-100

Akwa Ibom-57

Ogun-51

Ebonyi-48

Benue-44

Adamawa-42

Imo-38

Kwara-35

Gombe-32

Kaduna-31

Edo-29

Osun-29

Kano-24

Ekiti-15

Katsina-14

Delta-13

Nasarawa-13

Jigawa-10

Sokoto-3

Rivers-36

Niger-32

Oyo-32

Borno-29

Kaduna-27

Delta-18

Kwara-17

Cross River-9

Ekiti-8

Bauchi-7

Ogun-7

Sokoto-6

Bayelsa-3

Ènìyàn 1634 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.

Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 1634 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.

Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;

Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:

Lagos-440

Anambra-160

FCT-158

Rivers-134

Abia-103

Oyo-90

Enugu-81

Osun-73

Gombe-54

Kwara-50

Ogun-32

Plateau-32

Akwa Ibom-31

Ondo-24

Borno-23

Delta-23

Ebonyi-21

Taraba-21

Bayelsa-16

Kaduna-15

Nasarawa-13

Jigawa-12

Bauchi-11

Kano-11

Zamfara-4

Sokoto-2

Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 676 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.

Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 676 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.

Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;

Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:

Lagos-227

Rivers-73

Niger-69

Plateau-56

FCT-50

Kano-44

Oyo-43

Ogun-27

Gombe-18

Ondo-15

Enugu-10

Osun-10

Cross River-8

Edo-8

Nasarawa-7

Bauchi-4

Kaduna-3

Ekiti-2

Zamfara-2

Ènìyàn 685 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.

Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 685 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.

Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;

Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:

Lagos-355

Kaduna-58

Nasarawa-46

Kano-40

Akwa Ibom-33

Katsina-26

Ogun-25

Osun-21

Rivers-16

Edo-15

Oyo-13

Ondo-12

Borno-11

Ekiti-9

Kebbi-3

Plateau-2

Ènìyàn 1,883 míì tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.

Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 1883 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.

Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ.

Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:

Lagos-1040

FCT-298

Anambra-86

Rivers-54

Taraba-45

Ogun-42

Oyo-40

Akwa Ibom-38

Sokoto-30

Ebonyi-30

Imo-28

Kaduna-28

Osun-27

Kano-21

Benue-19

Edo-17

Gombe-15

Ekiti-9

Delta-8

Jigawa-3

Kwara-2

Bayelsa-2

Plateau-1

Èèyàn 1,114 míì tún ti lùgbàdì Covid-19 ní Nàijíríà, 1,577 ló ti kú báyìí

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.

Ninu ohun ta ri ka loju opo wọn ni Twitter eeyan 1114 tuntun mii lo lugbadi aarun yi.

Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ.

Skip X post, 3
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 3

Láì sí ìpínlẹ̀ Èkó níbẹ, àwọn tó lùgbàdì ààrùn Covid-19 lọ́jọ́bọ́ jẹ 864

Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade fọjọbọ ni Naijiria.

Ninu ohun ta ri ka loju opo wọn ni Twitter eeyan 864 tuntun mii lo lugbadi aarun yi.

Ipinlẹ Eko to maa n lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si ko si lori atẹ.

Abuja lo lewaju pẹlu 129 ti Anambra Rivers ati Benue si tẹle pẹlu 87,82 ati 80.

Ipinlẹ Oyo pọnwọ lewọn pẹlu eeyan 76.

Apapọ awọn ti aarun yi mu lọ ni Naijiria nilẹ oni to mọ si jẹ 1547.

Awọn to ri iwosan gba lapapọ ni Naijiria lati igba ti aarun ọhun ti bẹrẹ jẹ 100,853 bayi.Gbogbo awọn to lugbadi Covid-19 bayi wa ni isiro 127,024.

864 new cases of #COVID19Nigeria;

FCT-129

Anambra-87

Rivers-82

Benue-80

Oyo-76

Plateau-61

Kaduna-54

Delta-51

Nasarawa-38

Kwara-36

Edo-32

Katsina-26

Kano-24

Taraba-18

Ogun-14

Sokoto-11

Gombe-10

Jigawa-7

Akwa Ibom-6

Cross River-6

Zamfara-5

Bauchi-5

Osun-4

Ekiti-2

Coronavirus tún ṣekúpa èèyàn méjìlélógún, ẹni 1,861 míì tún kó

Ọwọja aarun Covid-19 ni Naijiria tun ti n gbori soke pẹlu bi eeyan 1,861 tuntun mii ṣe lugbadi aarun ọhun lọjọru.

Ninu akọsilẹ ti ajọ to n gbogun ti aarun yi fi sita loju opo wọn, eeyan mejilelogun lo ku ti apapọ awọn to ri iwosan si jẹ 100,365.

Lọjọru yi kan naa ni aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu ofin eyi to sọ di ẹsẹ fẹnikẹni ti ko ba lo ibomu.

Ijiya ẹwọn oṣu mẹfa ni aarẹ fi lelẹ fẹnikẹni ti o ba kọ lati wọ ibomu ni ita.

Bẹẹ naa ni ofin yi tun fi gbogbo awọn ilana to wa nilẹ tẹlẹ rinlẹ.

Ni apapọ bayii iye awọn to ti lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria ti di 126,160.

Atupalẹ bi nkan ti ṣe ri ree lawọn ipinlẹ kọọkan.

1,861 new cases of #COVID19Nigeria;

Lagos-773

FCT-285

Oyo-138

Rivers-111

Plateau-92

Nasarawa-83

Kaduna-59

Enugu-57

Imo-57

Edo-43

Kano-27

Kwara-20

Ebonyi-19

Abia-17

Ogun-12

Osun-12

Katsina-8

Bayelsa-6

Bauchi-5

Delta-5

Borno-4

Jigawa-4

Zamfara-1

Èèyàn màrúndínlógún kú, 1,303 míì tún ti lùgbàdì Covid-19 ní Nàijíríà lọ̀jọ̀ Ìṣẹgun

Lọjọ Iṣẹgun, eeyan mẹẹdogun lo padanu ẹmi wọn lọwọ aarun Covid-19 gẹgẹ bi ikede lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijria NCDC ṣe sọ.

Ninu atupalẹ awọn to lugbadi aarun naa, wọn s bakan naa pe eeyan 1,303 tuntun mii lo ko aarun yi ti awọn ejidinlọgọrinleniirinwo si wa lati ipinlẹ Eko.

Abuja tẹle Eko pẹlu eeyan ọkanlelẹwaalenigba.

Nassarawa, Rivers ati ati Kwara lo pọnwọ lewọn lori atẹ.

Lapapọ iye awọn to lugbadi aarun naa ni Naijiria bayi jẹ 124,299 ti awọn to si ba aarun naa lọ jẹ 1,522

Èèyàn 1,430 míì tún ti lùgbàdì Covid-19 ní Nàijíríà, 1,507 ló ti kú báyìí

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 1,430 lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Aje kaakiri orilẹede Naijiria.

Ẹrinlelogojilelẹẹdẹgbẹrin eeyan lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti ọgọrun wa lati ipinlẹ Plateau.

Mẹtadinlọgọrin wa lati Oyo, mejilelọgbọn lati ipinlẹ Kwara ti marun un si wa lati ipinlẹ Ekiti.

Lapapọ eeyan 112,996 lo ti karun naa lorilẹede Naijiria bayii, nigba ti 98,359 ninu wọn ti ri iwosan.

Eeyan 1,507 ni arun covid-19 ti ṣekupa ni Naijiria.

Èèyàn méjì kú, 964 míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Nàìjíria

Ikede iye awọn to lugbadi Covid-19 ti ajọ NCDC gbe jade lọjọ Aiku ni Naijiria ṣe afihan adinku diẹ ninu awọn to lugbadi aarun naa.

Lẹnu ọjọ mẹta yi, bi kii wọn maa gbe iroyin eeyan to kọja ẹgbẹrun koda a ti ri eyi to le ni ẹgbẹrun meji eeyan to lugbadi aarun naa ti wọn fi sita.

Ni bayi, wọn ni eeyan 964 tuntun mi lo lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria ti awọn meji si padanu ẹmi wọn.

Ipinlẹ Eko naa si ni ibi ti ọwọja aarun yi ti pọju lọ pẹlu eeyan 36o ti Jigawa ni eyi to kere julọ pẹlu eeytan mẹrin.

Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:

Lagos-360

FCT-88

Ogun-73

Imo-72

Kaduna-67

Plateau-57

Abia-41

Osun-41

Rivers-32

Kano-26

Niger-24

Benue-23

Edo-20

Cross River-20

Akwa Ibom-8

Nasarawa-6

Zamfara-6

Ekiti-6

Jigawa-4

121,566 confirmed

97,228 discharged

1,504 deaths

Lọ́jọ́ abamẹ̀ta àwọn èèyàn 1,633 tún lùgbàdì Covid-19 ìpínlẹ̀ Èkó tí padà sórí àtẹ

Ipinlẹ Eko ti wọn ko kọkọ fi sori atẹ ipinlẹ tawọn eeyan ti lugbadi arun Covid-19 lọjọ Ẹti ti pada soke bayi pẹlu eeyan mejidinlẹẹdẹgbẹta to lugbari aarun naa.

Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita loju opo wọn ni Twitter, eeyan to ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria bayi jẹ 1,633.

Eeyan marun un mii lo padanu ẹmi wọn lọwọ aarun yi ti o si mu ki apapọ awọn to ku ni Naijiria bayi jẹ 1,502.

Awọn tara wọn ya ti di eeyan 95,901 ti apapọ awọn to ti ko aarun naa si jẹ 120,602.

1,633 new cases of #COVID19Nigeria;

Lagos-498

Plateau-214

FCT-176

Rivers-99

Kaduna-98

Edo-87

Anambra-86

Akwa Ibom-50

Osun-47

Kano-40

Oyo-40

Kwara-39

Ebonyi-28

Niger-28

Taraba-28

Ogun-27

Ondo-21

Ekiti-12

Katsina-7

Borno-6

Delta-2

120,602 confirmed

95,901 discharged

1,502 deaths

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 1,483 tún lùgbàdì Covid-19 lánàá, ìpínlẹ̀ Èkó kò sí lórí àtẹ lọ́jọ́ Ẹtì

Ikede iye awọn to lugbadi Covid-19 ni Naijiria ti ajọ NCDC gbe jade gẹgẹ bi iṣe wọn ko sọ nkankan nipa iye awọn to lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko.

Gẹgẹ bi ajọ naa ti ṣe sọ , yatọ si iroyin Eko ti wọn ko gbe sita, aṣikọ waye ninu iye awọn to lugbadi aarun naa ni Zamfara.

Dipo eeyan mẹta to yẹ ki wọn kọ, eeyan kan ṣoṣo ni wọn sọ pe o lugbadi aarun ọhun.

Lori oke tente ni ipinlẹ Kaduna wa pẹlu eeyan 545 to lugbadi aarun naa nibẹ ti Abuja siu tẹle lẹyin pẹlu eeyan 235.

Niger lo ni iye eeyan to kere julọ ti apapọ eeyan to ni aarunnaa ni Naijiria lọwọ yi si jẹ 118, 138.

Atupalẹ awọn ipinlẹ to ku ree:

1483 new cases of #COVID19Nigeria;

Kaduna-545

FCT-235

Plateau-127

Nasarawa-80

Oyo-72

Delta-65

Rivers-64

Kano-46

Ogun-46

Bayelsa-30

Gombe-30

Abia-28

Osun-27

Edo-25

Ondo-14

Sokoto-12

Zamfara-10

Bauchi-8

Imo-5

Jigawa-4

Ekiti-4

Borno-4

Niger-2

Èèyàn 1, 964 tún lùgbàdì covid 19 lánàá, ìpínlẹ̀ Eko kó 824 nínú wọn!

1964 new cases of #COVID19Nigeria;

Lagos-824

FCT-246

Plateau-166

Kaduna-128

Ogun-76

Nasarawa-74

Anambra-69

Edo-50

Rivers-45

Ondo-44

Niger-40

Oyo-38

Adamawa-35

Kano-31

Akwa Ibom-27

Gombe-19

Kwara-13

Ekiti-12

Delta-6

Kebbi-6

Bauchi-5

Ebonyi-4

Osun-3

Zamfara-1

Covid-19 ti ṣekúpa èèyàn 1,478 báyìí ní Nàìjíríà, 92,336 ti jàjàbọ́

Covid-19 ti ṣekúpa èèyàn 1,478 báyìí ní Nàìjíríà, 92,336 ti jàjàbọ́

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1386 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.

Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 114,691 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.

Awọn 92,336 ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan jẹ Ọlọrun nipe.

Lagos-476

Rivers-163

FCT-116

Kaduna-114

Oyo-68

Plateau-62

Ogun-56

Imo-55

Osun-55

Edo-51

Anambra-50

Kwara-44

Kano-17

Ebonyi-14

Cross River-10

Delta-10

Jigawa-8

Bayelsa-6

Ekiti-6

Borno-2

Taraba-2

Zamfara-1

Gẹgẹ bi akọsilẹ yii, ipinlẹ Eko lo si n ni awọn to pọ julọ to ni arun coronavirus ni Naijiria.

Ìpínlẹ̀ Eko ló ń léwájú nínú àwọn tó lùgbàdì Covid 19 lánàá- NCDC

Ibi ni ọrọ de duro lori itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19 ni Naijiria:

Lagos-551

FCT-209

Oyo-83

Plateau-65

Kaduna-64

Enugu-61

Rivers-44

Ondo-39

Benue-37

Akwa Ibom-31

Kano-19

Delta-18

Gombe-18

Ogun-16

Edo-15

Kebbi-10

Ebonyi-9

Jigawa-4

Osun-3

Zamfara-3

Borno-1

Nasarawa-1

Coronavirus tún ṣekúpa èèyàn mẹ́rìnlá lọ́jọ́ Ajé, ẹni 1,617 míì tún kó

Ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria tun ti kede pe eeyan 1,617 lo ko arun coronavirus lọjọ Aje, ọjọ kejidinlogun oṣu kinni ọdun 2021 yii.

Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ NCDC, eeyan mẹrinla mii ni covid-19 tun ṣekupa lọjọ Aje eyi to mu di 1,449 to ti gbẹmi mi bayii nipasẹ covid-19 ni Naijiria.

Ipinlẹ Eko lo tun siwaju ninu awọn ipinlẹ to larun naa julọ pẹlu eeyan 776 lọjọ Aje.

Mẹtalelaadọta lo lugbadi arun ọhun lati ipinlẹ Ogun, marunlelogoji l'Osun.

Wọnyii ni atupalẹ iye awọn to lugbadi arun covid-19 ni Naijiria lọjọ Aje:

Lagos-776

Kaduna-147

Kwara-131

FCT-102

Plateau-78

Edo-59

Ogun-53

Osun-45

Rivers-37

Taraba-36

Nasarawa-34

Adamawa-33

Kano-26

Delta-20

Ebonyi-16

Bayelsa-11

Gombe-11

Borno-2

Lapapọ, eeyan 112,004 ni akọsilẹ fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria nigba ti 89,939 ti ri iwosan.

Èèyàn 1444 ló tún kó coronavirus lórílẹ́èdè Nàijíríà lọ́jọ́ Àìkú

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 1444 lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Aiku kaakiri orilẹede Naijiria.

Ẹẹdẹgbẹrun eeyan lekan(901) lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti 136 wa lati ipinlẹ Plateau.

Mẹrinlelaadọta wa lati Abuja, mọkandinlọgbọn lati ipinlẹ Osun, mẹrindinlogun lo ko arun naa nipinlẹ Oyo.

Eeyan mejidinlọgbọn lo ni coronavirus nipinlẹ Ogun lọjọ Aiku, .

Lapapọ eeyan 110,387 lo ti karun naa lorilẹede Naijiria bayii, nigba ti 89,317 ninu wọn ti ri iwosan.

Eeyan 1,435 ni arun covid-19 ti ṣekupa ni Naijiria.

Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 1,420 ló ti kú báyìí

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede loju opo Twitter rẹ pe eeyan 1,598 lo tun ko coronavirus lọjọ Abamẹta kaakiri orilẹede Naijiria.

Ọta le ni irinwo lekan(461) o lekan ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko eyi to pọ julọ.

Olu ilu Naijiria Abuja lo ṣe ipo keji nibi ti igba eeyan o le mẹfa ti lugbadi coronavirus lọjọ Abamẹta.

Eeyan 168 lo ni covid-19 nipinlẹ Rivers, mọkandinlaadọta l'Ogun, ọgbọn lati ipinlẹ Oyo, mọkanla l'Ondo nigba ti eeyan meje karun naa l'Ekiti.

Wọnyii ni atupalẹ iye awọn to lugbadi arun covid-19 ni Naijiria lọjọ Abamẹta:

Lagos-461

FCT-206

Plateau-197

Rivers-168

Kaduna-116

Anambra-53

Ogun-49

Ebonyi-47

Edo-42

Sokoto-32

Imo-31

Katsina-31

Oyo-30

Akwa Ibom-27

Delta-16

Kano-16

Abia-15

Niger-15

Ondo-11

Bayelsa-10

Borno-9

Kebbi-8

Ekiti-7

Jigawa-1

Lapapọ, eeyan 108,943 ni akọsilẹ fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria nigba ti 85,367 ti ri iwosan.

Skip X post, 4
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 4

Eeyan 1,420 lo ti ba arun coronavirus lọ ni Naijiria.

Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ lórí ṣíṣí iléèwé padà lọ́jọ́ Ajé bí èèyàn 1867 ṣe kó covid-19 lọ́jọ kan ṣoṣo

Ẹgbẹrun meji eeyan o din dẹ(1867) lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Ẹti lorilẹede Naijiria.

Eyi ni igba akọkọ tawọn to ni covid-19 ni Naijiria lọjọ kan yoo pọ to bayii.

Ipinlẹ Eko lo si n lewaju pẹlu awọn to larun naa julọ, ẹẹdẹgbẹrin eeyan le ni mẹtala(713) lo karun ọhun nipinlẹ Eko nikan lọjọ Ẹti.

Ipinlẹ Plateau to wa ni ipo keji nibi ti ọta le lugba eeyan o le mẹtala(273) ti karun naa.

Eeyan mọkandinlọgọrin lo ko covid-19 l'Oyo lọjọ Ẹti, mẹtadinlogoji l'Ogun ati Osun.

Skip X post, 5
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 5

Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa nipinlẹ kọọkan ni Naijiria ṣe lọ ree:

Lagos-713

Plateau-273

FCT-199

Kaduna-117

Oyo-79

Enugu-58

Ondo-53

Kano-49

Sokoto-43

Ogun-37

Osun-37

Nasarawa-36

Rivers-28

Benue-24

Delta-24

Niger-24

Gombe-18

Edo-15

Taraba-12

Bayelsa-10

Ekiti-9

Borno-6

Zamfara-2

Jigawa- 1

Eeyan 107,345 lo ti larun covid-19 lapapọ kaakiri orilẹede Naijiria bayii, eeyan 84,535 lo ti ri iwosan nigba ti ti 1,413 ti ba arun coronavirus lọ.

Nibayii, ọpọ eeyan lo ti kọminu pẹlu ikede ijọba apapọ pe ki awọn ileewe wọle pada lọjọ Aje, ọjọ kejidinlogun oṣu kinni ọdun 2021.

NCDC àti NYSC bẹ̀rẹ̀ ìpàdé lórí ṣíṣí ìpàgọ́ àwọn àgùnbánirọ̀

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu ajọ agunbanirọ, NYSC, lori ṣiṣi ipagọ awọn agunbanirọ abala keji ti ọdun 2020 kaakiri Naijiria pada.

Ninu atẹjade ti NDCD fi lede loju opo Twitter rẹ, o ni wọn yoo ṣe ipade ita gbangba kan lori ayelujara lati jiroro lori bi ipagọ naa yoo ṣe lọ laisi ibẹru pe awọn agunbanirọ yoo lugbadi arun Coronavirus.

Nibi ipade ọhun ti yoo waye loju opo ibaraẹnisọrọ Zoom ni NDCD, pẹlu ajọṣepọ NYSC ati PTF yoo ti da awọn ọdọ naa lẹkọọ lori awọn ohun to yẹ ki wọn ṣe lati dabo bo ara wọn.

Ibi ti o ti le ṣe iforukọlẹ lati kopa ninu ipade naa ree.

Ẹwẹ, ajọ yii kan naa tun ti kede pe eeyan 1,479 miran ti lugbadi arun naa ni Naijiria.

Apapọ awọn to ni arun ọhun bayii ti pe 105,478, awọn 83,830 ti ri iwosan nigba ti awọn 1,405 ti jẹ |olọrun nipe.

Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa nipinlẹ kọọkan ni Naijiria ṣe lọ ree:

Lagos-697

FCT-201

Nasarawa-80

Plateau-74

Rivers-72

Edo-46

Adamawa-43

Osun-39

Akwa Ibom-35

Delta-31

Anambra-27

Oyo-24

Kano-21

Abia-19

Enugu-19

Ogun-18

Sokoto-12

Bauchi-7

Taraba-7

Ekiti-4

Gombe-4

Imo-4

Bayelsa-2

Jigawa-2

Zamfara-1

Èèyàn mẹ́sàn án kú, 1,398 míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Nàìjíria

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,398 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.

Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 103,999 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.

Awọn 82,555 ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan 1,382 jẹ Ọlọrun nipe.

Eko -542

FCT-131

Oyo-120

Rivers-113

Plateau-111

Kaduna-71

Kwara-71

Akwa Ibom-34

Sokoto-31

Benue-28

Ogun-27

Kano-26

Kebbi-17

Osun-12

Nasarawa-11

Delta-10

Gombe-10

Bayelsa-9

Borno-9

Edo-8

Ekiti-3

Jigawa-2

Katsina-2

Kìí ṣe gbogbo àwọn tó ní Covid-19 ló ń ṣàfihàn àpẹrẹ rẹ̀, ẹ ṣọ́ra ṣe o - NCDC

Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti ni kii ṣe gbogbo awọn to ni arun Coronavirus lara lo maa n ṣafihan awọn apẹrẹ rẹ, nitori naa ki awọn ara ilu ṣora ṣẹ.

NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, nibi to ti sọ pe ọrọ naa ti di oju lalakan fi n ṣọri bayii.

Bakan naa lo tun kede eeyan 1,270 tuntun to tun ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria.

Gẹgẹ bi ikede ọhun ṣe sọ, eeyan mejila tuntun miran lo ku lọjọ Iṣẹgun nitori arun ọhun ni Naijiria.

Ni bayii apapọ iye eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria ti wọ 102,601.

Bi awọn ipinlẹ to ṣẹṣẹ tun ni arun naa ṣe lọ ree.

Lagos-435

FCT-234

Oyo-103

Plateau-86

Rivers-71

Enugu-51

Nasarawa-41

Delta-39

Edo-39

Osun-33

Niger-31

Sokoto-23

Ondo-16

Taraba-13

Ebonyi-12

Kano-10

Abia-9

Bauchi-7

Imo-5

Katsina-3

Gombe-1

Iye àwọn tó ń ní Covid-19 ti ń pọ̀ ju ilé ìwòsàn lọ, tó bá yá ọwọ́ wa ò ní ka mọ́ - NCDC

Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti sọ pe ọrọ Covid-19 ti n kọja oju ẹ, ati pe o ṣeṣe ki ile iwosan má le gba iye awọn to n lugbadi arun naa mọ bayii.

Adari ajọ ọhun, dokita Chikwe Ihekweazu lo fi ọrọ naa lede ninu awọn atẹjade kan loju opo Twitter rẹ nigba to n sọrọ lori bi arun naa ṣe n peleke si ni Naijiria lati nnkan bi oṣu kan sẹyin.

O ni ibẹru itankalẹ arun naa bẹrẹ si n pọ si lẹyin ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ to n risi eto iforukọsilẹ ati nọmba idanimọ, NIMC, pada ṣenu iṣẹ lẹyin idaṣẹsilẹ ranpẹ ti wọn gunle, ti obitibiti ero si ya bo ileeṣẹ wọn.

Bi ẹ ko ba gbagbe, ọpọ ero bẹrẹ si n ya bo ileeṣẹ naa ni kete ti ijọba apapọ paṣẹ fun awọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ pe ki wọn ja okun ila awọn ti ko ba forukọsilẹ fun nọmba idanimọ NIN lọjọ kẹrinla, oṣu Kejila, ọdun 2020.

Nnkan bii ọgọjọ miliọnu awọn ọmọ Naijiria ti ko fẹ padanu ila ipe wọn lo bẹrẹ si n ṣu bo awọn ẹka ileeṣẹ NIMC ọhun kaakiri Naijiria, eyii ti NCDC sọ pe o lagbara ran itankalẹ arun Coronavirus lọwọ.

Àkọlé fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé

Ṣugbọn ọrọ naa dojuru lẹyin ti awọn oṣiṣẹ NIMC daṣẹ silẹ nitori ibẹru pe arun ọhun le de wọn lalejo bi ọpọ ero ṣe n ya bo ileeṣẹ wọn.

Ẹwẹ, ajọ NCDC tun ti kede eeyan 1,244 miran to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria.

Nibi ọrọ de duro bayii, apapọ awọn to ti ni arun naa ni Naijiria je 101,331.

Bo tilẹ jẹ pe eeyan 80,491 lo ti ri iwosan gba, awọn 1,361 lo ti jẹ Ọlọrun nipe.