Lórí Irọ́: Ilúmọ̀ọ́ká oníṣòwò fún bàbá "Lórí Irọ́" lẹ́bùn owó gọbọi

Oríṣun àwòrán, Others
Ọtitọ lọrọ awọn agba to wi pe ba ọ ku, iṣe o tan.
Ọrọ ti Ọgbẹni Gbadamosi Ismail ti ọpọ mọ si baba Lori Irọ sọ pe Eledua ti fi iran han oun ninu ala pe oun yoo di ilumọọka ti n wá sí imuṣẹ bayii o.
Ọpọ lo ti n sọrọ baba yii lori ayelujara fun bi ọjọ diẹ sẹyin bayii.
- Ta ni gbajúgbajà òṣèré Funmi Martins ìyá Mide-Martins àti kí ló ṣekú pa á lẹ́ni ọdún 38?
- Wo obìrin méjì tó ń fi ìbásùn inú yìyín "Snow" ṣara rindin kí ọlọpàá tó ká wọn
- Ìjọba sọ̀rọ̀ lórí ìròyin tó ní Benin Republic fẹ́ di ìpínlẹ̀ kẹtàdínlógójì ní Nàìjíríà
- Wo iye kọ́ńdọ́mù táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ń ṣara rindin lọ́dún
- 'Àṣẹ ni! Gbogbo àgbàlagbà gbúdọ̀ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ṣáájú 31 July'
Iyẹn nikan kọ o, ni bayii, gbajugbaja onisowo kan ti fun baba lori irọ ni ẹbun ẹgbẹrun lọna igba owo naira(₦200,000).
Ko tan sibẹ o, oniṣowo yii tun fun baba Lori Irọ ni ẹbun foonu to to ẹgbẹẹrun owo naira.
- Wo oríṣi oúnjẹ márùn ún tí kò wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n tí àwọn kan fẹ́ràn púpọ̀ ní Nàìjíríà
- Wo àwọn ohun méje tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ngozi Okonjo-Iwealla àti ọkọ rẹ̀ Ikemba
- Ọwọ́ tẹ Sani fọganáísà tó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin ẹni ọdún 15 lò pọ̀ tó fi kú
- Kíní ìtumọ̀ àyájọ́ Ọ̀jọ ''Ash Wednesday' tó wáyé lóní?
- Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano ṣèrànwọ́ ₦18.5m fún àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ rẹ̀ tó faragbá nínú rògbòdìyàn tó wáyé ní Sasa
- Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa gbajúmọ̀ oníwàásù 'Lórí irọ́'









