Sexually transmitted diseases: Kọ́ńdọ́mù 587 mílíọ̀nù lọmọ Nàìjíríà ń lò lọ́dún

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadii kan ti ajọ Aids Healthcare center gbe jade ni ifọwọsowọpọ pẹlu ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun AIDS, NACA ati NOIPolls ti fihan pe ọrinlelẹẹdẹgbẹta o le meje rọba idaabobo condom lawọn ọmọ orilẹede Naijiria n lo lọdun.
Amọṣa iwadi naa tun jẹ ko di mimọ pe bilisnu kan o le aadọja miliọnu rọba idaabobo kọndọọmu lorilẹ-ede Naijiria nilo lọdọọdun lati lee dẹkun ọwọja arun ibalopọ lorilẹede Naijiria.
Awọn ajọ naa tun fi idi iwadii wọn mulẹ peiye alafo to wa laarin iye to wa nilẹ ati iye ti orilẹede yii nilo jẹ ọtalelẹẹdẹgbẹta ati mẹrin, 564.
Iwadii ijinlẹ naa tun sọ ọ di mimọ pe awọn eeyan ẹkun aringbungbun ariwa (North Central), aringbungbun guusu (South-south) ati ariwa gusu (South east) orilẹede Naijiria lo n lo kọndọmu julọ.
- Wo nkan márùn-ún tí o kò mọ̀ nípa ìbálòpọ̀ láàrin tọkọ-taya
- Ìjì òtútù pa èèyàn 21 ní Amẹ́ríkà, ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ míràn ń dojúkọ ìṣoro àìsíná ẹ̀lẹ́ńtíríkì
- A fẹ́ kí ìjọba fòfin de àwọn darandaran tó máa ń fi ìbọn Ak47 da málúù láàrín ìlú- MURIC
- Ẹ fura o! Nàìjíríà ń pín lọ díẹ̀ díẹ̀ rèé- Abdulsalami
- Buhari kéde ìlú kò fararọ lásìkò yìí- Ilé Igbimọ̀ Aṣofin Nàìjíríà
Bakan naa lo tun fi kun un pe awọn ọkunrin n lo kọndọmu ju awọn obinrin lọ.
- Wo àwọn ohun méje tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ngozi Okonjo-Iwealla àti ọkọ rẹ̀ Ikemba
- Ọwọ́ tẹ Sani fọganáísà tó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin ẹni ọdún 15 lò pọ̀ tó fi kú
- Ọmọ Nàìjíríà Invictus Obinwanne Okeke rẹ́wọ̀n ọdún mẹwàá he l'Amerika lórí ẹ̀sùn jìbìtì $11m
- Wo ohun 10 tó yẹ́ kó mọ̀ nípà Ọ̀gà EFCC, Abdulrasheed Bawa tí ààrẹ̀ Buhari yàn










