Akala burial: Òní ní Oloye Christopher Adebayo Alao Akala yóò wọ káà ilẹ̀ lọ ní Ogbomoṣo

Eto Isinku Alao Akala
Àkọlé àwòrán, Akala wọ kaa ilẹ pẹlu isin idagbere ẹlẹyẹ nla

Oloogbe Alao Akala wọ kaa ilẹ lọ ni ilu Ogbomoso.

Opolopo awọn eekan ni Naijiria lo peju pesẹ sibi eto isinki gomina ipinlẹ Oyo nigba kan ri, Oloye Christopher Adebayo Alao Akala.Wo àwọn ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Alao Akala tó dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 71

Nibẹ naa ni gbogbo ero ati ẹbi ati ara ati iyekan oloogbe ti wa ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un ni ilu abinibi rẹ ni Ogbomoso ni ipinlẹ Oyo to wa ni Iwo oorun guusu Naijiria.

Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Àkọlé fídíò, 'Ká tó rí irú Akala, ó di "century" míì, kò sí olóṣèlú kankan tó máa ń ṣilẹ̀kùn rẹ̀ fún wa l'Ogbomoso'
Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Àkọlé àwòrán, Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Àkọlé fídíò, Mo mọ èsì ọ̀rọ̀ kẹ̀, Queen Salawa Abeni ló kọ́kọ́ ta sí mi pé èmi 'Alaragbo ọmọ bàbá olójú kan' ní 1980s - Kuburat Alaragbo
Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Eto Isinku Alao Akala
Akala s burial

Oríṣun àwòrán, @Oyo State Govt

Àkọlé fídíò, 'Ká tó rí irú Akala, ó di "century" míì, kò sí olóṣèlú kankan tó máa ń ṣilẹ̀kùn rẹ̀ fún wa l'Ogbomoso'
Alao akala

Oríṣun àwòrán, @Alao Akala

Àkọlé àwòrán, Alao Akala

Oni, ọjọ kejidinlogun, oṣu keji, ọdun 2021 ni wọn yoo sin ara Alao Akala ni Ogbomoso.

Oloye Christopher Adebayo Alao Akala to ti tukọ ipinlẹ Oyo ri doloogbe ni aarọ kutu ọjọ Ru, ọjọ kejila, oṣu kinni, ọdun 2022.

Ile rẹ to wa ni ilu rẹrr ni Ogbomoso ni ipinlẹ Oyo ni Guusu Iwo oorun Naijiria ni ọlọjọ ti wa mu Akala lọ.

Ta ni Alao Akala ti wọn n sin loni?

Ọjọ Kẹta, Osu Kẹfa, ọdun 1950 ni wọn bi gbajugbaja oloselu, Christopher Adebayo Alao-Akala.

Alao-Akala lọ si ile iwe Government Technical College, Tamale, Ghana ati Ogbomoso High School, Ogbomoso.

Àkọlé fídíò, BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe

Nigba to pari nibẹ, o tẹsiwaju lọ si ile iwe giga fasiti ti ilu Ibadan.

Lẹyin naa lo bẹrẹ isẹ ọlọpaa titi to fi gba oye ADC si Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Naijiria.

Àkọlé fídíò, Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu