Alaafin burial: Mọ̀ síi nípa ìgbésẹ̀ tó ń wáyé ní aàfin lẹ́yìn ìpapòdà Oba Lamidi Adeyemi

Lati ọjọ Abameta, Ojọ kẹtalelogun, oṣu kẹrin, ọdun 2022 nti Oba Lamidi Adeyemi ti waja ni aaya ti bẹ silẹ to bẹ si are ni ilu Oyo.Wo ohun tó yẹ kó mọ nípa Baràá ibùgbé ìkẹyìn Aláàfin Olayiwola Adeyemi
Lati igba naa si ni eto orisiirisii ti bẹrẹ titi ara Iku Baba Yeye fi wọ kaa ilẹ lọ ni Baraa lẹyin ti wọn kirun si Oba Atanda Olayiwola lara tan ni aafin OyoIrú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo.

- 'Aláàfin ti rí ikú rẹ̀ ṣáájú ọjọ́ tó wàjà, ó sọ̀rọ̀ sílẹ̀ kó tó kú'
- Ẹ yé fi ìpapòdà àwọn lọ́balọ́ba ìpínlẹ̀ Oyo kọmi lọ́rùn - Gómìnà Seyi Makinde
- Wo àwọn òrékelẹ́wà tí yóò ṣe opó lẹ́yìn Aláàfin Oba Adeyemi tó papòdà
- Mọ̀ síi nípa Olorì Abibat Nihinlola Adeyemi tó ti lo ọdún 60 gẹ́gẹ́ bíi olorì láàfin Alaafin Oyo
- Wo ohun tí o kò mọ̀ nípa Morenikeji Lasisi, olórí ẹrú tó ti bá Aláàfin mẹ́ta ṣiṣẹ́
- Mọ̀ nípa Baṣọ̀run ìlú Oyo, Oloye Yusuf Akinade Ayoola tí yóò delé de Aláàfin tuntun
- "Kòríkòsùn lèmi àti Alaafin ṣùgbọ́n kété táwọn kan kẹ́ẹ́fín pé èmi láàyò ni gbogbo nǹkan dojúrú." Badirat Ajoke, olorì tẹ́lẹ̀ kẹ́dùn Alaafin
- Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn olòrì Alaafin Adeyemi àtàwọn tó bá fẹ́ fẹ́ wọn
- Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi
Oro Ije bẹrẹ loni ni Oyo:
Oni ọjọ́ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹrin, ọdun 2022 ni o pe ọjọ keje ti Oba Lamidi Adeyemi re iwalẹ aṣa.
Awọn Oniṣẹsẹ ṣeto Orò Ije fun Alowolodu to lọ darapọ mọ awọn baba nla rẹ.
Content is not available
View content on FacebookBBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.End of Facebook post, 1
Láti oju ite ni awon egbe awo ati awon omo ode ti rin pada sii ààfin Kabiyese
Wo awọn iṣẹlẹ Manigbagbe to waye nibẹ ninu fọnran fidio yii:
Content is not available
View content on FacebookBBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.End of Facebook post, 2
Kini awọn ọjọgbọn ninu itan sọ?
Ọ́jọgbọn Ogundiran sọ pe ''Pipadanu iru aaye aṣa bayi a ko le sọ iru ipa ti yoo ni nitori bo ba fi le parun, adanu nla leleyi yoo jẹ ti ko si ṣe maa ba ni feti gbọ rara ati rara''
Ẹwẹ,a gbọ pe Ogundiran ti ṣaaju kan si Alaafin Lamidi Adeyemi ko da si ọrọ atunṣe oori awọn Oriade yi nigba to ṣi wa laye.
A ko ribi fidi ọrọ naa mulẹ ṣugbọn ko jọ pe Alaafin to jẹ olugbelarugẹ aṣa ati iṣẹṣe Yoruba ṣe nkankan lori atunṣe Bara.
Boya bayi ti Alaafin naa ti wọ kaa ilẹ sun nibẹ,awọn to n bọ́ lẹyin le wa ṣe atunṣe ati igbelarugẹ aaye yi ko ba le jọju bo ti ṣe tọ ati bo ṣe yẹ.

Mọ̀ síi nipa igbesẹ to n waye lẹ́yin ti Alaafin ti re iwalẹ aṣa ni Oyo.
Bi awọn kan ṣe n b eere nipa Ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ikú Alaafin Oba Lamidi Adeyemi rè éWo bí àwọn Alfa ṣe kírun sí Aláàfin lára àti ètò tó kàn láti gbé e wọ káà ilẹ̀
Naa ni awọn mii n beere sii nipa Ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn Olori Alaafin rè é léyìn tó wàjàWo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn olòrì Alaafin Adeyemi àtàwọn tó bá fẹ́ fẹ́ wọn

Oríṣun àwòrán, @Alaafinfacebook
Ọba Lamidi Adeyemi lo papoda lẹni ọdun mẹtalelọgọrin ni Ọjọ Kejilelogun, Oṣu Kẹrin, ọdun 2022 ni awọn mii tun n beere nipa bi eto isinku rẹ sẹ lọ.Wo bí àwọn Alfa ṣe kírun sí Aláàfin lára àti ètò tó kàn láti gbé e wọ káà ilẹ̀
Gbogbo ohun ti ẹ fẹ mọ nipa Oba Alowolodu, Iku Baba Yeye Atanda Olayiwola Adeyemi keta ni BBC Yoruba n mu wa fun un yin nitori pe a mọ pataki aṣa ati iṣe iran Oodua.Wo Alàáfin 43 tó jẹ́ láti ìgbà ìwásẹ̀ ṣáajú Lamidi Adeyemi tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wàjà
- Ẹ yé fi ìpapòdà àwọn lọ́balọ́ba ìpínlẹ̀ Oyo kọmi lọ́rùn - Gómìnà Seyi Makinde
- Wo àwọn òrékelẹ́wà tí yóò ṣe opó lẹ́yìn Aláàfin Oba Adeyemi tó papòdà
- Ààrẹ Buhari, Ooni Ile Ife, Obasanjo kẹ́dùn Alaafin Oyo tó wàjà
- 'Aláàfin ti rí ikú rẹ̀ ṣáájú ọjọ́ tó wàjà, ó sọ̀rọ̀ sílẹ̀ kó tó kú'
- Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé
- Ta ni Yorùbá ń pè ní Abọ́bakú?
- Aláàfin àti Ọba ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún mìí tó wàjà láàrin oṣù márùn-ùn péré
Eto isinku Alaafin gan an ko i tii waye
'Ètò ayẹ́yẹ́ ìsìnkú Oba Lamidi Adeyemi kòí tíì wáyé, àfọ̀mọ́ Aàfin ń lọ lọ́wọ́'
Onimọ nipa iṣẹṣe naa ni ilẹ Yoruba kii ṣe ilẹ Arabu, tabi ẹlẹsin Juu to fi mọ Kristẹni nitori naa o di dandan ki wọn sin Alaafin ni ọna ti ilẹ Yoruba bi o tilẹ jẹ pe wọn ti sin ni ọna Islam.

Ọjọ Kẹsan ati Ikẹtadinlogun ni awọn ọjọ pataki ti wọn yoo ṣe awọn ohun ti wọn fẹ ṣe ni ọna iṣẹṣe.
Ọba kọọkan lo ni ibi ti wọn yoo sin si ti wọn n pe ni Baare, idile kọọkan lo si ni iboji ti wọn maa n sin won si wa.Wo ohun tó yẹ kó mọ nípa Baràá ibùgbé ìkẹyìn Aláàfin Olayiwola Adeyemi
Tani yóò máa tukọ̀ aafìn Oyo lasiko yii?
Bashọrun ni yoo saaju titun afin to leyin ipapoda Alaafin.
Oloye Ifayemi Elebuibon ni ṣiṣe afọmọ afin ti Alaafin ilu Oyo ni yoo pari gbogbo eto isinku ọba
Eleyii ni yoo ṣi ọna silẹ fun ọba tuntun miran lati jẹ.
O ni Bashorun yoo ṣe ipade pẹlu ile ọba to kan, ti wọn yoo si bere lọwọ ifa bi wọn yoo ṣe yan ọba miran.
Lẹyin ti wọn ba yan ọba naa tan, ni iṣẹṣe yoo ṣẹṣẹ bẹrẹ fun ọba tuntun naa.

Oríṣun àwòrán, Others
Wọ́n máa'tó ṣe ayẹyẹ Ìje Alaafin Oba Lamidi Adeyemi
Ọba tuntun le e fẹ awọn iyawo Alaafin to ba wu u.
Ọba Lamidi Adeyemi Kẹta fi awọn iyawo to rẹwa lorisirisi silẹ ni aafin ko to wọ kaa ilẹ sun, awọn ti wọn n pe ni olori.
Awọn olori Alaafin pọ ti ko si ẹni to si le e sọ iye pato ti wọn jẹ ni gbangban.
Lara awọn iyawo ọba to waja naa ni Olori Abibat, Olori Memunat, Olori Damilola Olori Anuoluwapo, Olori Mojisola, Olori Ola Badirat, Olori Folashade, Olori Omobolanle, Olori Rukayat Abbey Adeyemi, Olori Rahmat Adedayo, Olori Mujidat, Olori Ajoke, Olori Omowunmi ati Olori Moji Queen Damilola.

Oríṣun àwòrán, @Alaafin
Amọ alukoro fun ile ọba ni awọn iyawo Alaafin n ṣe idaro iku ọba lọwọ, ti wọn yoo si ṣe gbogbo eto to yẹ lati ṣe eto to ye fun ọba to waja.
Lẹyin eyi ni awọn iyawo ọba le kuro ni afin lati tẹsiwaju ni ọna wọn.
- Ìyànjẹ ni fún ọmọ Naijiria tí mo bá fẹ̀yìntì báyìí- Osinbajo
- Àwọn ènìyàn Nàìjíríà fi ìdùnnú hàn bí ìjọba ṣe ṣí àwọn ibodè mẹ́rin mìíràn
- Ẹ dáríjìn mí ọmọdé ló ń ṣe mí, mo kábàmọ́ ìwà tí mo wú - Akẹ́kọ̀ọ́ Chrisland Schools
- Twitter ti gbà láti ta ojú òpó nàá ní $40bn fún Elon Musk, ọkùnrin tó lówó jù ní ayé
- Óṣe! Àwọn ọmọdé mẹ́rin pàdánù ẹ̀mí wọn bí wáyà iná ṣe já lé wọn lórí
- Lukman gbẹ̀yín ẹbí lọ bẹ́ orí ìkókó ti wọ́n sìn ní Abeokuta, àṣírí tú bó ṣe fẹ́ tàá
- Èsì àyẹ̀wò ohun tó ṣekú pa gbajúmọ̀ akọrin ẹ̀mí, Osinachi Nwachukwu ti jáde
- Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi
Kíni yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn Olori Alaafin tí wọ́n kò fẹ́ dúró ní Aafin mọ́ lẹ́yìn àfọ̀mọ́?
Amọ awọn to ba gba lati duro si afin ni ẹtọ lati duro si ibẹ, ti ọba tuntun yoo si ma a tọju wọn.

Oríṣun àwòrán, Olubusola Afolayan
Ko si ohun to n jẹ abobaku mọ.
Ọpọlọpọ awuyewuye lo jẹyọ lẹyin iku Alaafin paapaa lori ẹrọ ayelujara.
- Adájọ́ sún ìgbẹ́jọ́ síwájú lẹ́yìn tí afurasí kan tó lọ́wọ́ nínú ikú Timothy Adegoke ṣubú nílé ẹjọ́
- Ìyànjẹ ni fún ọmọ Naijiria tí mi ò bá fẹ̀hìntì báyìí- Osinbajo
- Àwọn olùdíje sípò Ààrẹ lẹ́gbẹ́ òṣèlú PDP túká, ìmọ̀ràn wọn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
- Njẹ́ o mọ̀ pé láàrín ìṣẹ́jú méjì, ọmọdé kan ń kú nítorí àìsàn ibà??
- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ nípa ikú Baálẹ̀ àti èèyàn méjì tó kú l'Ondo táwọn ọ̀dọ́ ń so ikú wọn mọ́ agbófinró lọ́rùn
- Àjọ NDLEA nawọ́ gán ọkùnrin tó lọ́wọ́ nípa ẹ̀sùn N3bn egbògi Tramadol tí Abba Kyari ń kojú
- Okùnrin tó so àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mọ́lẹ̀ bíi ewúrẹ́, tó sì nà wọ́n rí ẹ̀wọ̀n ogún ọdún he
- 'Mo dáríji ẹni tó pa mí lọ́kọ́, mò sì gbà kí àwọn ọmọ wa fẹ́ ara wọn'
- Emmanuel Macron borí Le Pen ní ìbò ààrẹ France
Lara ohun ti awọn eniyan sọrọ nipa rẹ ni ọrọ abobaku, ti awọn Yoruba ma n ṣe ni igba aye atijọ ti eniyan kan yoo tẹle ọba de saare, ni igbagbọ pe yoo ma a ṣe ẹru ọba ni ọrun alakeji.
Amọ Baba Elebuibon ni ko si ohun to jọ mọ ati pe ọdun 1935 ni awọn oyinbo ti fofin de asa naa nitori ko mu ọpọlọ dani.
Amọ o ni isinku ọba yoo mu ẹjẹ dani, amọ kii ṣe ti ọmọ eniyan.

Oríṣun àwòrán, Others




















