BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Aṣa
Ọ̀rọ̀ oyè Awujale tún gba ọ̀nà míì yọ, bí igbákejì alága ìdílé Funsegbuwa ṣe wọ́ àwọn èèyàn tó ya kúrò nínú ìdílé lọ sílé ẹjọ́, bèèrè N10bn
1 Owewe 2026
2:46
Fídíò,
Wo pàtàkì òrìṣà Vodu Dangbe, níbi táwọn olùjọ́sìn ti ń gbé ejò sọ́rùn, kẹ̀yìn sí ìbálòpọ̀, jíjẹ epo tàbí iyọ̀ ṣaájú ètùtù
, Duration 2,46
31 Ògún 2026
0:54
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 0,54
1 Owewe 2026
Ọbalayé tó kéré jùlọ lágbáyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 34
28 Ògún 2026
Ìrírí mi nígbà àkọ́kọ́ tí wọ́n gbé mi lọ sí Ilorin jẹ́ kí n mọ̀ pé àwọn tó wá fi tipá gbé mi lè pa mí – Tani Olohun
28 Ògún 2026
Tani Olohun ṣàlàyé ohun tó mú Sunday Igboho wá sílé rẹ̀, àti ọ̀rọ̀ tó bá ọ̀gá ọlọ́pàá Kwara sọ káwọn ọlọ́pàá tó wá fipá gbé e nílé tó lè kúrò lágbègbè rẹ̀
27 Ògún 2026
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu òfin gbogbo ogúnjọ́ oṣù Kẹ́jọ bíi àyájọ́ Ìṣẹ̀ṣe láì yẹ̀
20 Ògún 2026
Wo ohun mẹ́jọ pàtàkì nípa ọdún Iṣẹ̀ṣe nílẹ̀ Yorùbá tí ìjọba Oyo, Ogun àti Eko fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́
20 Ògún 2026
3:32
Fídíò,
Wo omi Atan tó ń ‘ṣe ìwòsàn, fún ni lọ́mọ’ ní Ikare Akoko, àmọ́ obìnrin tó bá fọwọ́ kàn án, nǹkan oṣù rẹ̀ yóò gbẹ
, Duration 3,32
19 Ògún 2026
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi àyájọ́ ọdún Sango àgbáyé tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Oyo
16 Ògún 2026
Pásítọ̀ Olùdásílẹ̀ ìjọ Ọlọ́run ṣàlàyé ìdí tó fi fẹ̀sìn Kristẹni sílẹ̀ di oníṣẹ̀ṣe tó sí pa orúkọ dà láti Felix sí Ifawamiri
14 Ògún 2026
Ooni Ile Ife kéde orúkọ ọmọbìrin rẹ̀ tuntun
11 Ògún 2026
Bí àṣekágbá ọdún Osun Osogbo ṣe ń lọ lọ́wọ́, ọlọ́pàá ṣèkìlọ̀ nlá fàwọn ọ̀daràn l'Osun
7 Ògún 2026
Ọọ̀ni fi N100m, ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ta Sunday Igboho lọ́rẹ láti ṣe àtìlẹyìn fún ikọ̀ aláàbò Ìru Ẹkùn
5 Ògún 2026
Obìnrin tó bá rí Olóòlù, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò gbẹ lorí ìdúró ni, èyí tó bá ya fídíò rẹ̀ bíi Wasilat láì ṣe ìràpadà, yóò kú tàbí ya wèrè láàárín ọjọ́ keje - Ìdílé Olóòlù
4 Ògún 2026
N kò kú o, ń kò sì ya Oloolu, àlàyé rèé lórí bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé - Wasilat
4 Ògún 2026
Ààfin Olubadan fọhùn síta lórí bí orí oyè Lekan Alabi, Abese Olubadan, ṣe sùn ìta
4 Ògún 2026
Olorì Oluwatosin bímọ obìnrin fún Ooni Ogunwusi lẹ́yìn oṣú mẹ́ta tí Olorì Maryam bí ìbejì
2 Ògún 2026
4:56
Fídíò,
Èmi àti Funke Akindele ò jà, ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé tí ẹ kò fi rí wa pọ̀ - Kamo State
, Duration 4,56
29 Agẹmo 2026
Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù
28 Agẹmo 2026
Àlàyé rèé lórí bí eégún Olóòlù ṣe dé Ibadan, ìdí tí kìí fi wọ bàtà tàbí fojú kan obìnrin
27 Agẹmo 2026
Oluwo dá ẹgbẹ́ lọ́balọ́ba lẹ́kùn ìdìbò Ìwọ̀ oòrùn Osun sílẹ̀, di alága láéláé, àwọn ọba míì fi èrò wọn hàn
21 Agẹmo 2026
Ifá kìlọ̀ fáwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò gómìnà l'Osun, àlàyè rèé
9 Agẹmo 2026
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
6 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology