Catholics in Nigeria: Father Mbaka ní kò sí wàhálà láàrín òun àti ìjọ Kátólìkì

Oríṣun àwòrán, Youtube Screengrab
Ìjọ Kátólìkì, ẹ jèbùrẹ́, ọmọdé ló ṣe èmi àtàwọn ọmọ ìjọ mi- Father Mbaka
Ẹniọwọ Ejike Mbaka, adari ijọ Adoration Ministries Enugu Nigeria, (AMEN) ti ọpọ mọ si Fada Mbaka titọrọ aforiji lọwọ ijọ Katoliki lapapọ lori awọn aṣiṣe rẹ gbogbo.
Ninu iwaasu rẹ lọjọ Aiku, Fada Mbaka rọ Ẹniọwọ Callistus Onaga to jẹ Biṣọbu ijọ Enugu lati forijioun at'awọnọmọ ijọ oun fun iwa ti wọn hu eleyi to taẹrẹ ba aṣọ ala ijọ naa.
- Èèyàn 28 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi tó dànù ní ìpínlẹ̀ Niger
- À ń ṣe ìwádìí lọ́wọ́ bí ''candle'' ṣe pa Kayode Badru ní ìpínlẹ̀ Eko - Ọlọ́pàá
- Mi ò bú Baba Adeboye, mo kàn gégùn-ún fún àwọn tí kò ṣàtìlẹyìn fún Oduduwa Republic ni- Sunday Igboho
- Wo orísun agbára tí Sunday Igboho gbójúlé tí ọwọ́ ẹnikẹ́ni kò fi le tẹ̀ ẹ́
- Emmanuel Abina, ọmọ Olùdarí ìjọ GOFAMINT, Elijah Abina jáde láyé lẹ́yìn ikú ìyàwó rẹ̀
- Àyànmọ́ ló mú mi pàdé Princess, èrò wa jọra wọn- Iyabo Ojo
Bakan naa lo tun kilọ fun awọn ọmọ ijọ rẹ pe ki wọn lọ ja ewe agbejẹ mọwọ lẹyin ti awọn kan ninu wọn fi ipa wọ olu ileejọsin ijọ Katoliki lẹkun naa lọjọru nigba ti o dawati.
"Mi o le ṣe lodi si ijo- ta ni mi?
Bawo ni eeyan to ti n ṣiṣẹ ninuijọ fun ọdun marundinlọgbọn bẹrẹ si tun ni maa ba ijọ naa ja. Gbogbo nnkan to wa ninu aye mi, ti ijọ ni."
Fada Mbaka ni ko si ija laarin oun ati Biṣọbu ẹkun naa tabi awọn alaṣẹ ijọ Katoliki rara bi otilẹ jẹ pe awọn kan fẹ ko ṣẹlẹ.
Fada Mbaka ni oun ko kansara sawọ ọmọ ijọ oun fun iwa jagidijagan ti wọn hu bikoṣe akitiyan wọn lati wa oluṣọagutan wọn nigba tiwọn ro pe o sọnu.
- Wo orúkọ mẹ́rìnlá tó làmìlaaka tí Lizzy Anjorin sọ ọmọ rẹ̀
- Ẹ wo bí Leke Adeboye, àwọn ọ̀dọ́ ìjọ RCCG ṣe gẹ irun wọn láti bú ọlá fún Dare Adeboye tó papòdà
- Báwo ni ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Kayode Badru ṣe ṣẹlẹ̀ ní Celestial Church of Christ ni Eko? ẹ wo ohun tí a mọ̀!
- Sultan Sokoto ní káwọn mùsùlùmí wojú ọ̀run fún oṣù tuntun láti parí àwẹ̀














