LASEMA Lagos: Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná

Ilẹeṣẹ to n risi ọrọ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ti ni ọkọ meji lo jona raurau ni agbegbe Anthony lọ si Gbagada, nipinlẹ Eko lẹyin ti ijamba ọkọ waye.
Ọkọ agbepo nla ni ijanu ọkọ rẹ da iṣẹ silẹ to si yi danu le ori ọkọ meji ti awọn ọkọ naa si jona raurau lẹsẹkẹsẹ.

Ninu atẹjade ti Ajọ LASEMA fi lede ni wọn ti sọ wi pe ajọ naa tete de ibẹ lati pa ina naa ki o tọ fa ijamba miran ni ibi iṣẹlẹ naa.
LASEMA ni awọn ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ to n risi ijamba ina ni ipinlẹ Eko, LASG ati ileeṣẹ ọlọpaa lati ṣe iwadii kunkun awọn ijamba ọkọ naa ṣe ipalara fun.

Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn ko le e sọ lọwọlọwọ iye eniyan to ba ijamba ọkọ naa lọ.
- Bí o bá ṣe ìdánwò àṣewọ'léeṣẹ́ ọmọogun òfúrufú, wo bí o ṣe le rí èsì rẹ̀ níbí
- Wo ọ̀rọ̀ Fani-Kayode sí akọ̀ròyìn "blog" tó ní lílù ìyàwó rẹ̀ bíi bàrà ló mú wọn túká
- Wo ohun to yẹ kóo mọ̀ nípa fọ́ọ̀mù 'self-certification' tí ìjọba àpapọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ àtàwọn tó kàn
- Wo ọjọ́ tí wòlíì Sotitobire yóò gba ìdájọ́
- Inú mi dùn lórí òfin títẹ àwọn àfipábánilòpọ̀ ní ọ̀dá - Foluke Daramola
- Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina
- Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọbalayé ní kò yàtọ̀ sí èèyàn lásán - Elebuibon
Amọ, wọn ni awọn doola ẹmi ati dukia awọn eniyan nigba ti wọn de ibẹ.








