Ilẹ̀ ń j'ẹ̀nìyàn, ìyá ìyàwó gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo tẹ́lẹ̀ Florence Ajimobi jáde láyé

Oríṣun àwòrán, Oyo Insight
Victoria Amudoaghan to jẹ iya iyawo gomina ipinlẹ Oyo nigba kan ri, Florence Ajimobi ti dagbere faye.
Gẹgẹ bi iroyin ti o tẹ BBC Yoruba, opin ọsẹ to lọ ni mama jade laye.
Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ni Gomina ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi jẹ Ọlọrun nipe ni tiẹ.
- Kókó nǹkan tí ẹgbẹ́ NINAS ń bèrè fún ní ibi ìpàdé UN General Assembly
- Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari
- Wo ohun táwọn ọmọ Nàìjíríà ti pàdánù lẹ́yìn tó pé ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí ìjọba ti f'òfin de Twitter
- Ọ̀gá ọlọ́pàá Èkó kàn sí ẹbí Monsurat tí ọlọ́pàá yìnbon lù
- Lébìrà tó jí iriniṣẹ́ iná mọ̀nàmọ́ná a fi ẹgba àtòrì méjìlá ṣara rindin kó lè kọ́ ẹ̀kọ́
- 'Ó lé ni akẹ́kọ̀ọ́ 1,000 tí àwọn ajínigbé kó láàrin oṣù kíni sí ìkẹjọ 2021'
- Ta ni Ola Ibironke, ọkọ Bimbo Oshin to dólògbé?
Ọmọbibi ipinlẹ Delta ni mama aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ti o si tun jẹ ọmọ ijọ Aguda nigba aye rẹ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa lori iṣẹlẹ naa laipẹ.








