Mọ̀ síi nípa Ola Ibironke, Dudu Heritage, ọkọ Bimbo Oshin tó jẹ́ gbajugbaja to n gbé iṣẹ́ olórin síta tó ṣáláìsí

Oríṣun àwòrán, others
Opọ awọn eeyan ni wọn ti n ṣe idaro Ola Ibironke to jẹ oludari Dudu Heritage to doloogbe.
Koda awọn akẹgbẹ Bimbo Oshin to jẹ oṣere fiimu Yoruba lo ti lọ si ile wọn ni agbegbe bodija nibadan. Ara ore ojulumo ti pejopo lati kedun.
O jẹ ẹni to n ba awọn eeyan gbe orin jade.


O gbe ni ilẹ America fun ọpọlọpọ ọdun ko to ko pada wa si Naijiria.
Dudu Heritage jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Osun.
Ola Ibironke kawe gboye ni Naijiria, o tun ka ni London ati America.
Lọdun 2005 ni iroyin ni o gbe Bimbo Oshin niyawo.

Oríṣun àwòrán, others
Oluwa fun wọn ni ọmọ meji: Michael Olusegun Ibironke ati Iyanuoluwa Ibironke.

Ikú dóró! Dudu Heritage, olówó orí Bimbo Oshin ti jáde láyé
Ola Ibironke, ti ọpọ eeyan mọ si Dudu Heritage to jẹ ọkọ fun gbajugbaja oṣerebinrin Bimbo Oshin ti jade laye.
Iroyin naa ni ọkunrin naa deede subu ni nilu Ibadan.
Ola Ibironke gbe nilẹ America fun ọpọlọpọ ọdun ko to pada wa si Naijiria wa
- Odunlade Adekola yarí lórí ìròyìn tó ní ó n bá àwọn obìnrin sùn kó tó fi wọ́n sínú fíímù rẹ̀
- Ẹ dákun ẹ ran Iyabo Oko lọ́wọ́, ìyá ti ń ṣàárẹ̀ láti ọdún márùn ún sẹ́yìn, o ti kọjá agbára wa- Foluke Daramola Salako
- Ṣọ́ọ̀ṣì wó pa èèyàn méjì ní Taraba, àwọn míràn farapa
- Ọwọ́ ti tẹ ọlọ́pàá tó yìnbọn pa ọmọ ọdún 18 nílùú Eko
- Ìyàwó Wòlíì TB Joshua di olórí ìjọ Synagogue
- Ọmọ Naijiria tó ń ṣe Yahoo rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ̀rin he l'Amẹrika

Oríṣun àwòrán, @Dudu
Titi di asiko yii a ko tii le sọ ohun to pa a ṣugbọn ẹbi wọn ti fidi iṣẹlẹ naa mulẹ pe Ola Ibironke ti doloogbe.
Wọn ni pe o deede ṣubu ni lale ọjọ Aiku ni Ibadan.
Dudu Heritage n gbero lati gbalejo awọn agbabọọlu ẹyin ori papa gọọfu ni Naijiria laipẹ fun idije to m bọ lọna ni ọlọjọ de.
- Kí ló lè mú ẹni ọdún mẹ́tàlélógún tó wà ní ND2 yìí pokùnso?
- Wo díẹ̀ lára bí wọ́n ṣe sàmì ìrántì ìkọlù 9/11 ní America
- Okòòwò márùn ún tí o lè bẹ̀rẹ̀ nínú ilé rẹ̀
- Aàrẹ Joe Biden pè fún alàáfíà àti ìrẹ́pọ̀ lẹ́yìn ogún ọdún tí ìkọlù 9/11 wáyé ní America
- Ọ̀kan lára àwọn ọmọ Odunlade Adekola nídìí iṣẹ́ tíàtà sọ̀rọ̀ sókè lórí ẹ̀sùn pé ó ń bá àwọn lòpọ̀













