Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC

Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba jẹ ọkan lara eto akanse ti BBC Yoruba ṣagbekalẹ rẹ fun igbadun ẹyin ololufẹ wa.
Eto naa jẹ ajọṣepọ ẹgbẹ awọn Onimọ Yoruba, iyẹn Yoruba Studies Association of Nigeria àti apapọ ẹgbẹ Akomolede Naijiria.
Ipinlẹ Eko ni a ti bẹrẹ pẹlu awọn akọsẹmọṣẹ Olukọ lati ipinlẹ Eko
Arabinrin Olaitan Zainab kọ nipa iwe: Ọrẹ Mi ninu ẹkọ oke yii.
Ile iwe Gbagada Girls Junior school ni olukọ wa ti wa.
o ṣalaye iru oju ti ọrẹ meji fi wo ọkunrin kan ti wọn pade ti ọkan fi oju tẹmbẹlu rẹ amọ oun gan lo pada n wa lati fa oju rẹ mọra tori owo
- Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀
- Mo ṣetán láti dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ bá ọ̀rọ̀ ajé Eko jẹ́- Sanwo Olu
- Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS
- Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní...
Ṣe ẹ ranti bi inu kilaasi yin ṣe maa n ri lasiko ti ẹ ba fẹ ka awọn iwe ayọka Yoruba nigba ti ẹ ṣi wa nileewe girama?
Arabinrin Faleke lo kọ wa nipa oge sise ninu ẹkọ ti Oke yii.
Ile iwe Ikeja Central Primary School ni olukọ wa lori oge ṣiṣe ti wa.
Oge sise laye atijọ ati laye ode oni pẹlu awọn apẹrẹ loriṣiriṣi ni wọn fi kọ wa lọsẹ naa.
Oriṣi ẹya litireṣọ Yoruba to wa ati ọna ti koowa n gba jẹyọ ni alagba Lawanson Olumuyiwa kọ wa ninu ti oke yii.
Litireṣọ alohun ati apilékó tun jẹyọ pẹlu awọn apẹẹrẹ to yẹ ni a gbe yẹwo
Arabinrin Adeyẹmọ lati Oke Ira Junior High school yannana Isọri Orọ Yoruba.
Apola Orukọ ni olukọ wa sọrọ ni kikun le lori.
Mọ sii nipa ẹka isọri ọrọ Yoruba.
Aya Peters sọ ohun ti apola orukọ jẹ lati ile iwe Ogba Junior Grammar school.
Awọn akoonu gbolohun kọọkan ati koṣeemani ninu ọrọ Yoruba ni Olukọ wa ṣlaye fun wa.
Eyin Olukọ Yoruba ni ipinlẹ Eko ati alaga ati awọn oloye ẹgbẹ Akomolede to ku, BBC n dupẹ lọwọ yin fun iṣẹ takuntakun ti ẹ ṣe ti ẹ fi kọ wa ni awọn koko ọrọ wọnyii.
- US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?
- 'Cartoon' nípa Anọbi Muhammed kó Ọ̀jọ̀gbọ́n kan sí ìyọnu ní Egypt
- Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀
- Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní...





















