Èdè Yorùbá: Àjọ̀dún àádọ́ta ọdún Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà

Ayẹyẹ lati dawọọ Ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba Naijiria ti wọn da ẹgbẹ ọhun silẹ.
Ilu Kabba nipinlẹ Kogi ni eto naa ti bẹrẹ lọjọ karun un oṣu kẹjọ, eto yii yoo tẹsiwaju di ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ ko to kasẹ nilẹ.
Aarẹ ẹgbẹ naa ninu ọrọ ikini sibi ipade naa fawọn oloye ẹgbẹ lami ẹyẹ fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti ṣe.
- Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now'
- Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó
- Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà
- Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa
- Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka
- Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni
Wọnyi ni diẹ lara aworan to ṣapejuwe bi eto naa ṣe lọ niluu Kabba nipinlẹ Kogi














