35th Lisabi Day: Àwòkọ́se rere ni Lisabi jẹ́ fún ọ̀dọ́ láti jẹ́ ògo Ẹ́gbá àti ilẹ̀ Yorùbá lapapo- Oba Gbadebo

Aláké gbá àwọn odò lamoran láti yàgò fún wíwà owó òjìji
Kabiyesi, Ọba Adedotun Aremu Gbadebo, Aláké tí ilé Ẹ̀gbá tí gbá àwọn odò níyànjú láti yàgò fún ìwà janduku.
O rọ̀ wọ́n làti jawo kúrò nínú ọ̀nà eburu láti wá owó òjijì ati fifi ipa wa ọlà.
- Àjọ̀dún Lisabi Agbongbo Akala tọdún 2022 ti bẹ̀rẹ̀ ní Abeokuta
- Ibá Lassa fojú hàn ní ìpínlẹ̀ Oyo, ó ti mú ẹ̀mí Dókítà méjì lọ
- Bàbá Adesola Adedeji, ọ̀kan lára àwọn afurasí méje ń fẹ́ rọ́pò ọmọ rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ ikú Timothy Adegoke
- Ibá Lassa fojú hàn ní ìpínlẹ̀ Oyo, ó ti mú ẹ̀mí Dókítà méjì lọ
- Kíni àjọ ECOWAS ilẹ̀ Adúláwọ̀ ń sọ báyìí lórí ìjà Russia àti Ukraine?
- Òní ní Baba Ijesha tún fojú ba iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn bíbá ọmọdé lòpọ̀
- Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie
- Ọmọ ọdún 15 tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó bá ọmọ ọdún mẹ́jọ lòpọ̀ fojú balé ẹjọ́ l'Eko
- Ilé ẹjọ́ fi Rahman Adedoyin pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n bí ìgbẹ́jọ́ ikú Timothy Adegoke ṣe bẹ̀rẹ̀ l'Osun

Òní ni Aláké gba amoran yìí lásìkò tí ó ṣe ìwúre níbí òkúta olumo láti sayajo ọdún Lisabi Eelekaarundinlogoji irú ẹ ti o wáyé nílùú Abẹ́òkúta tí ń ṣe olú ìlú Ìpínlẹ̀ ogún.
Aláké, lo tún jé olórí Ọba ní ìlù Egba ni wíwà owó lọ́nà eburu àti wíwú ìwà jagidijagan ni ó ń ṣokùnfà bí àwọn odò ṣe ń kú ikú òjijì láwùjo wá.
Ó fi kún pé ìwà ibaje yóò dinku tí àwọn odò bá lè tẹnpele mọ wíwú ìwà ọmọlúwàbí.
Ọba Gbadebo ni àwokose réré ni Lisabi jẹ fún àwọn odò láti lè tá ògo ìlú Ẹ̀gbá àti ilẹ̀ Yorùbá lapapo jí.
Ayẹyẹ Ayajo ọdún Lisabi ọdun yìí ni àwọn lekan lekan tí peju pèsè ṣe láti ṣe ìwúre lórí òkúta olumo , kíkọ orin ògo Ẹ̀gbá àti ṣíṣe àwọn onírúurú àfihàn àṣà ilẹ̀ Yorùbá míràn hàn.

Lára àwọn ènìyàn jankanjankan tí wọ́n pèsè síbí ayéye Lisabi ọdún yìí ni a ti rí Ààrẹ Ona Kàkànfo ile Yorùbá, Ibà Gani Adams, Oba Agura tí Gbagura, Abdul Sabur Bakir.
Awon mii tun ni Olú tí ìlú itori, Ọba Akorede Abdlfatai Akamo, Balogun Ẹ̀gbá, Sikirulahi Atobatele àti àwọn jankan jankan mìíràn.

Ayẹyẹ Ayajo Àjọ̀dún Lisabi, Eelekaarundinlogoji irú ẹ ti ọdún yìí tí bẹ̀rẹ̀ ni ìlú Ẹ̀gbá.
Àjọ̀dún Lisabi Agbongbo Akala tọdún 2022 ti bẹ̀rẹ̀ ní Abeokuta
Ni ilu Abẹ́òkúta tí ń ṣe olú ìlú Ìpínlẹ̀ Ogún níbí tí àwọn ọmọ bíbí Ẹ̀gbá, Oba, ìjòyè tí màá ṣe ajoyo àṣà, àti isese wọ́n.
- Ilé ẹjọ́ fi Rahman Adedoyin pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n bí ìgbẹ́jọ́ ikú Timothy Adegoke ṣe bẹ̀rẹ̀ l'Osun
- Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó wà ní Ukraine yóò máa dé láti òní lọ- Mínísítà fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè
- Òní ní Adájọ́ Ojo sún ìgbẹ́jọ́ Timothy Adegoke sí lẹ́yìn ohun tó sẹlẹ̀ ní Osogbo lánàá
- Ṣé lóòtọ́ ni Sunday Igboho ti gba ìtúsílẹ̀ nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n Benin Republic?
- Wo iye èèyàn Ukraine àti àjòjì tó ti kú láti ìgbà tí Russia ti gbógun ti Ukriane
- Ìjọba àpapọ̀ fún Amẹ́ríkà láṣẹ láti gbé Abba Kyari fún ìgbẹ́jọ́

Ayeye odun Lisabi yii wa láti fi ṣé ìrántí àwọn akọni wọn bí LISABI AGBONGBO AKALA, SODEKE pelu awon mii ti won ti ja fun ominira Egba ti won si ti teri gbaso.

Koda, odun yii tun wa fun sisami àwọn òun isenbaye bí ÒKÚTA OLUMO àti àwọn nkan mèremère míràn.
Kini pataki ọdun naa?
Lara pataki ohun tí wọ́n fi ń sàmì ayẹyẹ náà ni wọ́n tí lọ sí orí òkúta Olumo lónìí tí ń ṣe ọjọ́ kẹrin, oṣù kẹta.
Nibe ni Kabiyesi Aláké tí ilé Ẹ̀gbá, Oba Adedotun Arẹwà Gbadebo Okunkenu kẹrin tí o tún ṣé olórí Ọba ní ekun Egba gba adura itesiwaju Egba kaakiri agbaye.
Bakan naa lo ko àwọn ọmọ bíbí Ẹ̀gbá, ìjòyè àti ará lọ sí ọjà itoku láti lọ ṣe ìwúre àti kíkọ orin ògo Ẹ̀gbá.
















