Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Ansoogun ati awọn ẹru ati ẹṣọ rẹ ti wọn jọ m bọ lati oju ogun lo di okuta oriṣiiriṣi lori apata yii- Baba Iresa
Bi ọmọ ko ba ba itan ni ọrọ akọni Oodua, Ansoogun....
Ansoogun jẹ jagunjagun to gbona nigba aye rẹ.
- Mọ̀ sií i nípa Oba Yesufu Asanike , Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- Ìdí tí wọn kii fi jẹ́ kí obìnrin jẹ Ọ̀ọ̀ni ni Ile Ife
- Mọ̀ síi nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ ríru tó mú ẹ̀mí 16,000 èèyàn lọ tó sì ba dukia $206b jẹ́
- Àwọn Ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn
- A ti fòfin de dída màálù ní gbangba káàkiri ilẹ̀ Yorùbá, Ibò àti ìhà Gúúsù Gúúsù - Àwọn gómìnà yarí
- Kí ló mú Yomi Fabiyi àti Iyabo Ojo máa sá aṣọ ìdọ̀tí ara wọn síta?
Ansoogun lọ jagun lójó kan ni o gba iroyin ibanujẹ nigba to n pada bọ wa sile lo ba binu wọlẹ to si di okuta ni agbegbe Iresa Adu nijọba ibilẹ Suurulere ni Ogbomoso ni ipinlẹ Oyo ni guusu iwọ oorun Naijiria.
Koda, kii ṣe Ansoogun nikan lo di Apata nla o, gbogbo ẹru ati ẹṣọ to wa pẹlu rẹ lasiko naa lo sọ di apata yika ara rẹ ni agbegbe naa.
- Ikú kò m'ọmọdé, kò màgbà, ẹ gbàdúrà fún ìdílé mi àti aya pẹ̀lú ọmọ olóògbé- Pásítọ̀ Adeboye
- Bó ṣe nípasẹ̀ ọkada ni tàbí ọkọ̀ ojú omi tàbí láti inú ihò ilẹ̀, ẹ wá ọ̀nà láti fi Naijiria sílẹ̀- Pasitọ Paul Adefarasin
- Ẹ ò lè rí Covid-19 nínú ìjọ mi, ẹ má fi abẹ́rẹ́ rẹ̀ lọ̀ mí - Oyedepo
- Kàyèéfì! Wo ìdí tí àlùfáà ìjọ Aguda fi ń kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?
- Ọkùnrin kan bí ẹgbẹẹgbẹ̀rún ni mi, àmọ́ o le darapọ̀ mọ́ ìwọ́de fún Baba Ijẹsha tí o ba tako ìfìyàjẹni
Oloye James Olawale to jẹ Baba Irasa ni Irẹsa Adu lo farabalẹ ṣalaye ohun to ṣẹlẹ fun BBC Yoruba nigba ti a kan sibẹ.
BBC Yoruba n jade lọ kọ sii nipa awọn akọni Oodua ki yoruba ma baa parun ni.

Oloye Olawale salaye pe gbogbo nkan ti wọn fi n bọ oriṣa Ogun naa ni wọn fi n bọ Apata Ansoogun bii aja, Epo, ẹmu, obi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Koda, Oloye ni Baba Ansoogun to di apata yii a maa ranṣẹ beere fun ẹbọ nigab miran tabi fun etutu.
O ni Baba Ansoogun a maa gbọ adura loju ẹsẹ ni pe ko si ohun ti eeyan wa beere lọwọ rẹ ti kii ṣe fun ni.
- Wo ìtàn bí ààlọ́ ṣe bẹ̀rẹ̀ àti onírúurú ààlọ́ àpagbè àti àpamọ̀
- Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Ìjálá, Ìrèmọ̀jé àti oríkì ọ̀pọ̀ ẹranko ijù
- Ọmọ tí wọ́n bá fi èdè Yorùbá kọ́ ní ẹ̀kọ́ máa ń pegedé jú tí èdè míràn lọ- Ọjọgbọn Ogundeji
- Ṣé o rántí eré òṣùpá? Wo èré ìdárayá èyí tó yẹ fún àárọ̀ kùtù àti èyi tó wà fún òṣùpá
- Wo bí àrokò ṣe ń jẹ́ bí idán láyé àtijọ́ nílẹ̀ Yorùbá?
- Àwọn Olùkọ́ Yorùbá ní ìlú Ondo fọkọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá
Eewọ ti ojubọ apata yii ni ni pe Ọba kankan ko gbodọ foju kan apata Ansoogun.
Oloye ni iru Oba bẹẹ kọ lo maa pada sile lọjọ to ba dẹjaa
Idi niyi ti wọn fi maa n mu gbogbo Oba ni Ogbomoso wa si iloro ọna apata yii fun etutu ṣugbọn wọn ko ni jẹ ki Oba rin sori apata naa tabi ko sunmọ ọ ju lati fi oju kan apata naa.
Baba Irẹsa sọ awọn ẹkọ to yẹ ki iwa akóni Ansoogun yii kọ wa.
- Kàyèéfì! Wo ìdí tí àlùfáà ìjọ Aguda fi ń kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?
- Mọ̀ síi nípa èrò àti ìgbàgbọ́ nípa Olodumare lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá
- Àwọn ọmọ Naijiria yóò rí akitiyan ìjọba láti yanjú ètò àbò tó mẹ́hẹ láìpẹ́ - Lai Mohammed
- Eid al-Fitr: Wo àwọn ohun tó yẹ ki o ṣe sáájú ìrun Yidi fún ọdún ìtúnu ààwẹ̀
- Ogójì èèyàn ti pàdánù ẹ̀mí wọn nítorí ìjà tó ń wáyé láàrín Israel àti Palestine ní Lod




