Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Orukọ Olodumare sọ nipa awọn abuda adamọ Olodumare- Arabinrin Iyabo Ayinde.
Ero ati Igbagbọ Yoruba ninu Olodumare ni a n gbeyẹwo loni lori eto Akomolede ati Aṣa lori BBC loni.
Arabinrin Iyabo Ayinde lati ile ẹkọ Nigeria Navy Secondary School to wa ni Iresa- Apa ni Ogbomoso ni ipinlẹ Oyo ni oluko to yaranti to n kọ wa loni.
Olukọ wa ṣalaye ni kikun lori igbagbọ awọn babanla Yoruba ninu ẹsin si Olodumare.
O sọ nipa pataki ẹsin mẹtẹẹta ti Yoruba n gba fi sin Olorun.
Esin Ibilẹ, ti Imale ati Igbagbọ ni awọn Yoruba gbagbọ ninu rẹ ti wọn si fi n sin Olodumare pẹlu awọn ohun eelo ti igbagbọ wọn rọ mọ
- Agbọ́nmágbọ́ntán, Agọ̀mágọ̀jù, mọ̀ síi nípa àwọn orúkọ Ìjàpá nínú alọ àpagbè Yorùbá
- Àwọn Olùkọ́ Yorùbá ní ìlú Ondo fọkọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá
- Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí
- Àwọn Olùkọ́ Yorùbá ní ìpínlẹ̀ Osun ṣe bẹbẹ lórí ètò Akomọlede àti Aṣa lórí BBC
- Wo bí àrokò ṣe ń jẹ́ bí idán láyé àtijọ́ nílẹ̀ Yorùbá?
- Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Ìjálá, Ìrèmọ̀jé àti oríkì ọ̀pọ̀ ẹranko ijù
- Ọmọ tí wọ́n bá fi èdè Yorùbá kọ́ ní ẹ̀kọ́ máa ń pegedé jú tí èdè míràn lọ- Ọjọgbọn Ogundeji





