Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá
Ẹyan oríṣi meje ló wa ninu girama ede Yoruba.
Arabinrin Bunmi aya Femi Amao lati ile iwe Graceland Heights School ni agbegbe Wọfun, Olodo ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni olukọ wa fun toni.
Ọrọ Ẹyan ni koko girama ti an gbe yẹwo loni.
Ẹyan Asapejuwe ni o maa n sọ fun wa sii nipa ọrọ orukọ.
- Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
- Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀...
- Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, "Noun Phrase"
- Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC
- Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá
Eto Akomolede ati Asa yii n waye lati ọwọ BBC Yoruba pẹlu ajọṣepọ ẹgbẹ Onimọ Yoruba YSAN ati apapọ ẹgbẹ Akomolede Naijiria.
Oriṣi ẹyan meje to wa ni olukọ Bunmi Femi Amao kọ wa loni.
- Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan
- Ẹ̀rí tuntun BBC Africa Eye yìí tú àṣírí ohun tó ṣẹlẹ̀ gangan nínú ìbúgbàmù Abule Ado
- Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM
- Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀
- Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú
Eyan Ajorukọ
Ẹyan Aṣapejuwe
Eyan Asorukọ
Eyan Atọka Aṣafihan
Eyan Aṣonka
Eyan Arọpo Orukọ
Eyan Afarajorukọ
Eyan Awẹ gbolohun Afarahe Aṣapejuwe.
- Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM
- Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU
- Bí PDP ṣe na APC lálùbami ní Edo, bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣẹlẹ̀ ní Ondo- PDP
- Wo ìdí tí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo ṣe lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀
- Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí
- Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn Ṣója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon

