Ọlọ́jọ́ Festival 2020: Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú

Ọdọọdun ni ọdun Ọlọjọ maa n waye fun gbogbo ọmọ kaarọ, o jiire paapa awọn ọmọ Ile-Ifẹ ni ilẹ Yoruba.
Gẹgẹ bi iṣẹ lọdọọdun, Oba Ogunwusi ni yoo kọkọ side nipa wiwọ Ile-Odua ki o to wọ ade Aare lati jẹ ki ayẹyẹ naa bẹrẹ ni pẹrẹwu.

Lẹyin naa ni ayẹyẹ ti wọn n pe ni Gbajure yoo waye kaakiri awọn ojuko kan ni ilu Ifẹ, ti awọn araalu yoo si ma tẹle wọn kaakiri lati ṣe ajọyọ naa.
- Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan
- Sudan tí bẹ̀rẹ̀ ìjìròrò lórí bí US yóò ṣe yọ òrúkọ̀ wọn kúrò nínù ikọ̀ agbẹ́sùnmọ̀mí àgbáyé
- Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀
- Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò
Bakan naa ni Oba Ogunwusi yoo gbalejo awọn to ẹlẹsin Ogun, Sango ati Osun ni aafin ọba pẹlu ayẹyẹ lorisirisi.
Ni Ọjọ Keje to jẹ kokaari eto, Ooni yoo gbalejo ọpọlọpọ awọn eniyan lati okeere ati kaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wọn yoo wa lati wa ba wọn ṣe ayẹyẹ.

Ni ọdun to kọja, aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari to peju si ibi ayẹyẹ aṣekagba naa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ati gbogbo Adulawọ lagbaye lati ma ṣe gbagbe iṣẹṣe ati aṣa wọn.
- 'Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀'!
- Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump
- Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n...
- Àwọn agbófinró ti mú Eji tó jẹ́ igbákejì Ebila, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn "One Million Boys" sí gbaga
- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu










