Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Tọkọ taya tuntun ati oyun inu wọn naa ba iṣẹlẹ naa rin, iyẹn Chisom àti Emmanuel Uyamadu
Ibugbamu ni ipinlẹ Eko ati abajade iwadii ikọ BBC Africa Eye.
Lọjọ kẹẹdogun, oṣu kẹta \, ọdun 2020 lo ṣẹlẹ nibi ti ẹmi eeyan mẹtalelogun ba iṣẹlẹ naa rin.
Ajọ NNPC ni pe kii ṣe ẹbi wọn rara pe afẹfẹ gaasi ati ikọlu to waye lo faa.
Ile iwe Bethlehem Girls College lo fi ara gba iṣẹlẹ naa julọ ni eyi ti ẹmi Arabinrin Heniriatta Alokha sọnu sii to jẹ ọga ile iwe naa
Pẹlu ọpẹ ni awọn eeyan fi n sọ pe ẹmi akẹkọo kankan ko sọnu sinu iṣẹlẹ naa.
Ajọ elepo rọbi Naijiria di ẹbi iṣẹlẹ naa kuro lori wọn ṣugbọn awọn eeyan ni ọpa epo to bẹ lo faa.
- Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
- 'Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀'!
- Ize-Iyamu: Èmi àti ẹgbẹ́ APC ṣì ń ṣàyẹ̀wò tó yẹ sí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo lọ́wọ́, a kò tíì mọ ohun tó kàn
- Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari
BBC Africa ṣe iwadii lori awọn fọnran fidio to jade ati awọn nkan miran lati fidi otitọ ọrọ yii mulẹ pe ọrọ ko ri bi NNPc ṣe sọ lori ibugbamu naa.