African Idols: Kí ló lè mú kí àlùfáà ìjọ Aguda máa kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?

Eewọ! A kii ri aja ni mọṣalaaṣi. Ẹ gbọ na, ki lo kan alufaa ijọ Aguda pẹlu awọn ere iṣẹnbaye?
Bẹẹ laa bi ni o. Ilumọọka alufaa ijọ Aguda kan nilẹ awọn Ibo, Rev Fr Paul Obayi lo n ko awọn ere iṣẹnbaye pamọ o.
Kini idi abajọ ti Rev Fr Obayi fi n ko ere pamọ nigba ti ki i ṣe olooṣa?
- Wo orísun agbára tí Sunday Igboho gbójúlé tí ọwọ́ ẹnikẹ́ni kò fi le tẹ̀ ẹ́
- Báwo ni ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Kayode Badru ṣe ṣẹlẹ̀ ní Celestial Church of Christ ni Eko? ẹ wo ohun tí a mọ̀!
- Ǹkan dé o! Àwọn jàndùkú tún yìnbọn pa ọlọ́pàá méje lẹ́nu iṣẹ́, wọ́n dáná sun ọkọ̀ wọn
- Mo gbé ìgbésẹ̀ láti ṣẹ́ oyún ọmọ mi tuntun, ọkọ mi nàá sì faramọ́ nítorí pé...
- Ẹ tú Baba Ijesha sílẹ̀ pẹ̀lú Béèlì, ẹ má ṣi agbára òfin lò bí bẹ́ẹ̀ kọ́
- Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀
Rev Fr Obayi ni oun n ko awọn ere iṣẹnbaye yii pamọ si ile ikonkan iṣẹnbaye oamọ si kawọn ọmọde to m bọ lẹyin wa ọla le lanfaani lati ri wọn.
Alufaa Obayi ni tawọn iran to n bọ lẹyin wa ọla ko ba ri awọn ere yii, wọn ko ni mọ itan iran ẹya Ibo.
''Mi o mọ idi tawọn alufaa atawọn ile ijọsin fi n dan sun awọn ere atawọn oriṣa ilẹ Ibo?''
Ibeere ti alufaa Obayi beere niyii nigba to ba awọn akọroyin sọrọ.
''Ọpọ ere iṣẹmbaye Igboukwu lawọn oloe ti jigbe lọ.
Ki lo n ṣẹlẹ bayii nipa ooṣa to wa nilẹ Ozalla?''
- Wo orúkọ mẹ́rìnlá tó làmìlaaka tí Lizzy Anjorin sọ ọmọ rẹ̀
- À ń ṣe ìwádìí lọ́wọ́ bí ''candle'' ṣe pa Kayode Badru ní ìpínlẹ̀ Eko - Ọlọ́pàá
- Èèyàn 28 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi tó dànù ní ìpínlẹ̀ Niger
- 30 nínú 40 àwọn tí wọ́n jígbé nínú Mọ́ṣáláṣí lásìkò Tahajjud ní Katsina ti gba ìtúsílẹ̀
- Amotekun Ondo ju afurasí ajínigbé mẹ́rin s'átìmọ́lé, dóòlà àwọn tí wọ́n jígbé
Ara awọn ibeere ti Rev Fr Obayi n beere niyii.
Ọpọ ere ati ooṣa iṣẹnbaye ni awọn to fi ẹsin abalaye silẹ di ọmọ lẹyin Kristi ti dana sun lẹyin ti wọn di onigbagbọ tan.
Amọ, Rev Fr Obayi n kaakiri ilẹ Ibo lati ko awọn ere iṣẹnbaye to ba ti gbọ pe wọn fẹ dan sun pamọ.
Koda, o mu awọn akọroyin lọ si awọn ojubọ to ti ko ọpọ ere ati ooṣa iṣẹnbaye to ti ko pamọ bayii.
- Ọkọ mi kò kú rárá- Arabinrin Temiloluwa aya olóògbé Dare Adeboye
- Ẹ̀mí ọlọ́pàá mẹ́tàlá ló sọnù lópin ọ̀sẹ̀ lọ́wọ́ àwọn "unknown gunmen"
- Orílẹ̀-ède UK ti fi kún iye òfin tó de àwọn arìnrìàjò wọn tó fẹ́ wá sí Nàìjíríà nítorí…
- Ènìyàn 49 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdí ààrùn Coronavirus ní Naijiria
- Ìjọba àpapọ̀ kéde Òjọ́rú àti Ọjọ́bọ gẹ́gẹ́ bi ísinmi lẹ́nu iṣẹ́
- Ìjọba dá òfin kónlé-ó-gbélé lórí àjàkálẹ̀ àrùn covid-19 padà














