1999 Constitution case: Adájọ́ sún ìgbẹ́jọ́ ẹjọ́ INEC àti Ilana Oodua ni Ado Ekiti lórí ìwé òfin Nàìjíríà 1999 síwájú

Lẹ́yìn o reyin ni ile ẹjọ giga ni Ado Ekiti ni Adajọ ti sun ẹjọ naa siwaju.
Saaju ni Ilana ọmọ Oodua to n ja fun ominira iran Yoruba kuro ni Naijiria ti gbe ajọ eleto idibo Ńaijiria, INEC lọ sile ẹjọ.
Igbejo naa waye lori koko pe ki eto idibo ma se waye ni ipinlẹ Ekiti laisi atunse si iwe ofin Naijiria ti ọdun 199 ti a n lo lọwọ ti wọn ni o kun fun kò tọ́.A kọ̀ láti yí ọkàn wà padà lórí ìpinnu Yorùbá Nation- Ilana Omo Oodua
- Mo ti 'ùnfollow' ẹ lórí 'social media'; Ọlọ́run a ṣe idajọ fún ẹyin méjèèjì- Iyawo Yul-Edochie
- Òní ni ọjọ́ mẹ́jọ ìpapòdà Oba Lamidi Adeyemi ni ìlú Oyo
- A ti yọwọ́ olùdíje méji kúrò láwo lẹ̀yìn àyẹ̀wò, wọn kò lè díje lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ PDP- David Mark
- Mọ̀ síi nípa Olorì Abibat Nihinlola Adeyemi tó ti lo ọdún 60 gẹ́gẹ́ bíi olorì láàfin Alaafin Oyo
- Wo bí ètò Orò Ìje Oba Lamidi Adeyemi to wàjà ṣe lọ ní Oyo
- Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi
- Mínísítà Nàìjíríà, Abubakar Malami, tó wà nídí ẹjọ́ Sunday Igboho ti darapọ̀ mọ́ ìdíje dupò gómìnà Kebbi
- Mo gbìyànjú láti ṣẹ́yún àkọ́bí mi saájú ìgbeyàwó - Iyabo Ojo
- Bíbéli mi ló sọ pé kí n fẹ́ ìyàwó omidan mẹ́rin, kìí ṣe ẹ̀ṣẹ̀- Pásítọ̀
Kini abajade nile ẹjọ́?
Lẹyin atotonu iko mejeeji ni Adajọ sọrọsoke.
Adajọ Agba Babs Kuewunmi ti ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ to wa ni ilu Ado Ekiti ti sun ẹjọ naa siwaju
Ejo naa ti ẹgbẹ Ọmọ Ilana Oodua gbe lo ile-ejo siwaju di ọjọ kọkanla oṣu karun-un, lori pe ko ní sí ibo gomina ni ipinle Ekiti, Osun ati lọdun 2023, Lai sí iwe ofin tuntun àti atunto orilẹ-ede Naijiria.

Awọn Ẹgbẹ ilana ọmọ Oodua ni wọn gbé agbefoba agba ati àjọ INEC lo sí ilè ejo lori eto idibo to n bo l'ekiti.

Kini o tun ṣẹlẹ nile ẹjọ?
Awọn oludahun ninu ẹjọ naa, agbẹjọro agba fun agbefoba agba ati ajọ eleto idibo orilẹ-ede ni kò sí ni kootu fún ẹjo naa.
Agbẹjọro fún àwọn olugbejo ilana ọmọ Oodua, agbẹjọro Tolu Babayemi sọ pé àwọn mu iwe ipejo lọ fún àjọ INEC ati Agbefoba àgbà (Anthony General).
Sugbon awon o mo idi ti won ko sí ilè ẹjọ loni, ti ọ sí tun sọ pe awọn yo tun lọ fún wọn ní ìwé miran lati fi ran won leti.
Adajọ Agba Babs Kuewunmi ti ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ to wa ni ilu Ado Ekiti ti sun ẹjọ náà siwaju sí ọjọ kọkanla oṣu karun-un.

Kini o ti kọkọ ṣẹlẹ?
Ìgbẹ́jọ́ Ilànà Ọmọ oodua àti Náìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ nílé ẹjọ́ ní Ekiti
Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua, ni pe ko ní sí ibo lọdun 2023, Lai sí iwe ofin tuntun àti atunto orilẹ-ede Naijiria ti wọn sì ti gbé àjọ INEC lo sí ilè ejo.
Àwọn aṣáájú ẹgbẹ Ilana Omo Oodua ti gbe INEC wa sí ile ejo ìjọba àpapọ̀ ti o wá ni ilu Ado-Ekiti lati da wọn lowo duro lati ma se ètò idibo gomina ni ipinle Ekiti ati Osun.
- 'Ẹran ẹtu ni mo yìnbọn sí, àmọ́ òkú ìmáàmù ni mo bá nígbà tí mo fẹ́ gbe e'
- Látàri ìjà Russia àti Ukraine, Bí a ṣe fẹ́ dènà ìyàn oúnjẹ ní Naijiria rè é- Buhari
- NDLEA sàmì sí ilé Abba Kyari mẹ́fà àti ilé ìtàjà tó ní ṣọ́ọ̀bù 100 ní Maiduguri fún ìwádìí
- Kìí ṣe nǹkan abàmì bí Alaafin, Soun àti Olubadan ṣe papòdà lèralèra - Elebuibon
- Mọ̀ nípa Baṣọ̀run ìlú Oyo, Oloye Yusuf Akinade Ayoola tí yóò delé de Aláàfin tuntun
- Kò sí Ilana Omo Oodua mọ́ ní UK, a fẹ́ ṣe àtúnṣe - Ilana Ọmọ Oodua
- To bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ Yoruba Nation, ìgbésẹ́ tó gbé rèé - Ilana Oodua
- Ká má rí! Kò sí aàyè fún ìdìbò Gómìnà ní Osun àti Ekiti- Ilana Omo Oodua
Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua ni eto idibo lati beere lọwọ awọn ọmọ Naijiria Iori bo ya won sì fẹ tẹsiwaju gẹgẹ bí orilẹ-ede kan gbọdọ wáyé ṣáájú ibo ọdún 2023.
Opolopo igba ni ẹgbẹ ọmọ Ilana Oodua pé iwe òfin ọdun 1999 ni jìbìtì, pé láìsí ìwé òfin tuntun, Yorùbá ń lọ.

Ẹgbẹ naa ni ohun ko ni fi iwa-ipa da awọn Olùdìbò duro, sugbon oun yoo lo agbara ti ofin ati awọn kootu, ni ibamu pẹlu ipinnu ati eto imulo ti a mọ daradara.

Gbogbo bi o ba se lo ni ile ẹjọ apapo ni Ado-Ekiti ni ikanni BBC news Yoruba o ma mu wa sí etí igbó ati ojú iworan yin.
- 'Ètò ayẹ́yẹ́ ìsìnkú Oba Lamidi Adeyemi kòí tíì wáyé, àfọ̀mọ́ Aàfin ń lọ lọ́wọ́'
- Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi
- Wo ohun tó yẹ kó mọ nípa Baràá ibùgbé ìkẹyìn Aláàfin Olayiwola Adeyemi
- Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo
- Ẹ yé fi ìpapòdà àwọn lọ́balọ́ba ìpínlẹ̀ Oyo kọmi lọ́rùn - Gómìnà Seyi Makinde
- Wo Alàáfin 43 tó jẹ́ láti ìgbà ìwásẹ̀ ṣáajú Lamidi Adeyemi tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wàjà
- Ẹ yé fi ìpapòdà àwọn lọ́balọ́ba ìpínlẹ̀ Oyo kọmi lọ́rùn - Gómìnà Seyi Makinde
- Wo Alàáfin 43 tó jẹ́ láti ìgbà ìwásẹ̀ ṣáajú Lamidi Adeyemi tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wàjà














