Senato Francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari lọ́dún mẹ́wàá sẹ́yin ní, bóyá kò bá rí i ṣe
Buhari kó ní agbárà mọ́, òun kọ́ ló ń ṣe ìjọba- Senato Francis Fadahunsi
Opo awọn ọmọ Naijiria lo ti n sọrọ ibi ti eto aabo Naijiria de duro labẹ iṣẹjọba aarẹ Buhari yii.
- Kò sí bí wọ́n á ṣe máa ka ọta ìbọn fún Sọ́jà tí a maa lè borí Boko Haram- Olagunsoye Oyinlola
- Kò tíì tó àsìkò pé kí Nàìjíríà pín ṣùgbọ́n...- Olowu ilẹ̀ Kuta
- Iṣẹ́ Oníbúrẹ́dì ní mo kọ́, ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló sún mi dé ìdí ẹ̀ṣà pípé tí mo fi là- Ajobiewe
- Ẹ dẹ́kun lílo Kurani àti Bibeli nìkan láti fi búra fún àwọn olóṣèlú wa, ẹ jẹ́ ká fí ńkan ìṣẹ̀mbáyé kún un- Oba Ogboni Iwase
- Ọ̀pọ̀ iṣẹ́ Èṣù táwọn èèyàn ń pariwo kò rí bẹ́ẹ̀, aṣe burúkú ṣe rere ni Èṣù
Senato Francis Adenigba Fadahunsi n ṣoju awọn ekun ipinlẹ Osun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP nile igbimọ aṣofin agba ni Abuja.

Oríṣun àwòrán, @fadahunsi
O ni pe agba ti de fun Buhari ni awọn to yii ka ṣe n baa ṣe ijọba rẹ.
O tun ṣalaye pe adura lo ku lasiko yii pẹlu awọn igbese akin.
- Ọkùnrin mẹ́wàá ló ti fipá bá mi lòpọ̀ rí, àbúrò ìyá mi lálákọ́kọ́- Oluwatobi Raji
- Wo ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ fún àgbà nọ́ọ̀sì tó ta ọmọ ọdún mẹ́fà ní N200,000
- Ìṣẹ̀lẹ̀ omíyalé yóò wáyé ní Eko, Oyo, Ogun, Ondo àti ìpínlẹ̀ 30 míì láàrín ọjọ́ mẹ́ta- NiMet
- Wo ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn márùn ún tí àwọn èèyàn ilú Eko fi kan àwọn òṣìṣẹ́ LASTMA
- Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ẹ̀bẹ̀ DSS láti dáwọn ọmọlẹ́yìn Sunday Igboho mẹ́rin tó gb'òmìnira padà s'atìmọ́lé
Fadahunsio ni ọ̀rs Afghanista ti kọ awọn oloselu lọgbọn pe ko seni ti ko le gba ijọba.
O ni 'Rebel' le gba ijọba ti agbofinro ba dawọ silẹ bi o ṣe n ṣẹlẹ laisko yii ni Naijiria.
- Tètè wá gbé òkú eèyàn rẹ bí bẹ́ẹ̀ kọ́ a ó sìn wọ́n papọ̀ mọ́ tí 200 lópin ọ̀sẹ̀- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá
- Ojú wa rí tó gẹ́gẹ́ bíi akẹ́kọ̀ọ́ UNIJOS kí Makinde tó wá fi mọ́tò kó wa padà sí ìpínlẹ̀ Oyo- Akẹ́ọ̀ọ́ UNIJOS
- Mẹ́fà nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ Islamiyya Tegina ti kú, àwọn ajínigbé ṣì ń bèèrè N200m
- Ǹkan kò lè dẹ̀rọ̀ ní Nàìjíríà láì ṣe pé á ní ìjọba míì nítorí Buhari ti dàgbà jù- Senato Fadahunsi
- Oṣù mẹ́ta ni mo lò nílé ìwòsàn lẹ́yìn tí 'Mopol' fọ́ ìgo 'Coke' lórí mi ní LASU- Babatunde Gbadamosi
- Wo ìgbésẹ̀ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Plateau gbé lẹ́yìn ìkọlù tó wáyé lónìí
Fadahunsi salaye ọna abayọ lori ọrọ awọn ṣọja ati ipa to yẹ ki onikaluku ara ilu ati akọroyin ko fun idagbasoke Naijiria lai yọ oloselu kọọkan silẹ.
- Òní ni àyájọ́ ọdún Udiroko nílùú Ado Ekiti níbi tí Ọba yóò ti jẹ iṣu tuntun
- Ọlọ́run nìkan ló lè ní kí Tinubu má jẹ ààrẹ lọdún 2023, ìmọ̀ràn lọ̀rọ̀ Yahaya Bello- Joe Igbokwe
- Àwa nìkan ni ọ̀nà àbáyọ sí ìṣoro tó ń dojúkọ Naijiria- Àwọn Oníṣẹ̀ṣe
- Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144
- Àjọ SERAP gbé Buhari lọ sílé ẹjọ́ lórí N106bn tí wọ́n ló d'àwátì láwọn ilé iṣẹ́ ìjọba
- Àwọn jàndùkú afẹ̀mí-ṣòfò ṣekúpa èèyàn 24 ní Kaduna àti Katsina lọ́jọ́ kan ṣoṣo