Nítorí kí Aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí- Olagunsoye Oyinlola
Wo ọ̀nà àbáyọ mẹ́rin láti fi borí ogun Boko Haram ní Nàìjíríà- Olagunsoye Oyinlola
Oloye Olagunsoye Oyinlola ba BBC soro ni kikun lori ohu to ṣokunfa ogun Boko Haram ni ariwa Naijiria.
O sọ ohun ti oju rẹ ri ni Maiduguri lasiko to fi wa lẹnu iṣẹ ologun nibẹ.
- Oṣù mẹ́ta ni mo lò nílé ìwòsàn lẹ́yìn tí 'Mopol' fọ́ ìgo 'Coke' lórí mi ní LASU- Babatunde Gbadamosi
- Àwọn ọmọ yahoo-yahoo mẹ́sàn-án ní ọwọ́ wa tẹ̀ nílé tí Dorothy ń gbé-EFCC
- Kò sí bí wọ́n á ṣe máa ka ọta ìbọn fún Sọ́jà tí a maa lè borí Boko Haram- Olagunsoye Oyinlola
- Mi ò bínú sí gbogbo nǹkan ti Chioma sọ nípa mi- Apostle Suleiman
- Ọlọ́run nìkan ló lè ní kí Tinubu má jẹ ààrẹ lọdún 2023, ìmọ̀ràn lọ̀rọ̀ Yahaya Bello- Joe Igbokwe

Oríṣun àwòrán, others