BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Aabo orile-ede
Gbogbo àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ Esinele gba ìtúsílẹ̀
wákàtí 9 sẹ́yìn
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo gbẹ̀mí afurasí ajínigbé méjì lójú ọ́nà Owo lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìbọn fúnra wọn
9 Agẹmo 2026
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
8 Agẹmo 2026
Ọmọ Naijiria méjì kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá àti lásìkò ìkọlù ní South Africa, ìjọba àpapọ̀ fọnmú, bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
8 Agẹmo 2026
Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà
7 Agẹmo 2026
Davido ṣàlàyé ìdí tó fi wọ aṣọ tórúkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso wà lára rẹ̀ níbí ìdíje World Cup
7 Agẹmo 2026
Ọmọ ọdún méjìlélógún ṣàlàyé bó ṣe jí ara rẹ̀ gbé, tó sì ń bèèrè N25m owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí rẹ̀
6 Agẹmo 2026
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
6 Agẹmo 2026
"N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀"
6 Agẹmo 2026
Àwọn agbébọn ṣèkọlù sáwọn àgbẹ̀ nínú oko, pa mẹ́sàn-án, jí ọ̀pọ̀ gbé lọ
6 Agẹmo 2026
Olórí ọmogun Naijiria ṣàlàyé ibi tí iṣẹ́ dé lori ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
5 Agẹmo 2026
VDM fẹ̀sùn kan Makinde pé ó san owó ìtúsílẹ̀ fun àwọn tó jí olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ gbé ní Oriire, wo ohun tí ìjọba sọ nípa rẹ̀
4 Agẹmo 2026
Bàbá àti ọmọkùnrin rẹ̀ mẹ́ta, afurasí ajínigbé tó ń fi màálù dídà bojú kó sí gbaga Amotekun l'Ondo
1 Agẹmo 2026
"Bí a ṣe kó sínu wàhálà lẹ́yìn tí wọ́n jí àwọn ọmọ wa gbé níbi tí wọ́n ti lọ ṣe ìdánwò"
30 Òkùdu 2026
"Èyi ni ohun tí Olúwa sọ fún mi nípa ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso" – Pásítọ̀ Adeboye
30 Òkùdu 2026
Ọlọ́pàá dóòlà ọmọdé méjì lọ́wọ́ ajínigbé l'Oyo, mú ọ̀daràn mẹ́rin pẹ̀lú oríṣiríṣi nǹkan ìjà olóró
30 Òkùdu 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérèégbè 'Operation Kosaye' tó gbérasọ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun
29 Òkùdu 2026
4:08
Fídíò,
Sunday Igboho: A lè kojú ajínigbé àti agbébọn táwọn ọba alayé àti àgbà Yorùbá bá tì wá lẹ́yìn
, Duration 4,08
29 Òkùdu 2026
Sunday Igboho ṣàlàyé ipò tí òun àtàwọn ẹ̀ṣọ́ Iru Ẹkun tó farapa nínú ìkọlù Old Oyo National Park wà
29 Òkùdu 2026
Wo ohun tí òfin nọ́mbà ìdánimọ̀ tí Aarẹ ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lù túmọ̀ sí fún ọ
28 Òkùdu 2026
A máa tó gba ọkọ̀ òfurufú láti dá ààbò bo ìpínlẹ̀ Oyo, a tún máa ṣí àwọn ilé ẹ̀kọ́ padà láìpẹ́ - Makinde
28 Òkùdu 2026
Àwọn agbébọn ló dojú ààbò ilẹ̀ Yorùbá délẹ̀, digbí là wá lẹ́yìn Sunday Igboho - Afenifere
26 Òkùdu 2026
"Ìjọba, olùkọ́, àwọn ọmọ wa ń fi ẹsẹ̀ gbálẹ̀, tẹ̀lé Eléégun kiri, ẹ ṣí ilé ẹ̀kọ́ padà"
26 Òkùdu 2026
Tinubu kéde ìgbésẹ̀ tuntun tí ìjọba rẹ̀ ń gbé láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
26 Òkùdu 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology