Minimum wage: NLC ló ń fa ọwọ àfikún owó òṣìṣẹ́ sẹ́yìn!

NLC

Oríṣun àwòrán, Others

Àkọlé àwòrán, Ìjọba àpapọ́ ní ẹgbẹ́ òsìsẹ́ tún bèrè fún àfikún owó osù fún àwọn tó ń gba owó osù tó ju 30,000 Naira tí wọn béré fún lọ.

ìjọba àpapò tí fẹ̀sùn kán àjọ àwọn òṣìṣẹ́ pé, àwọn ni wón ń fà ifaseyin bá ṣíṣe àfikún sí owó àwọn osise lórílẹ̀ èdè Naijiria.

Alága àjọ tí ń rí sí owó oṣù, àti ipòwòwọlé, Olóyè Richard Egbule, lo sọ ọrọ yìí ni Abuja nígbà tí ó ń fi ọ̀rọ̀ j'omi toro oro pelu àwọn akọ ròyìn lọ́jọ́ ajé.

Egbule ni Ìjọba àpapọ́ ní ẹgbẹ́ òsìsẹ́ tún bèrè fún àfikún owó osù fún àwọn tó ń gba owó osù tó ju 30,000 Naira tí wọn béré fún lọ.

Àkọlé fídíò, Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?

ìjọba àpapò wa fikun wi pe ti awọn ba fikun owo bi ẹgbẹ osisẹ se beere rẹ, iye owo ti ijọba a ma a san fun owo osu.