Aiye Confraternity: Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Aiye méjìdínlógún kò sí pámpẹ́ ọlópàá Ekiti lásìkò

Oríṣun àwòrán, Others
Ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti t i kéde pe awọn ti ribi mu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun mejidinlogun ni ipinlẹ naa.
Awọn olubi yi la gbọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun Aiye ti wọn si fura si pe wọn mọ nípa iku Ajayi Sunday ati Owolabi Moses ni oṣu kẹta ọdun yi.
Komisana ọlọpaa Ekiti, Moronkeji Adesina, sọ pé ni Ikole Ekiti láwọn ti mu afurasi mejidinlogun yi nibi ayẹyẹ igbanisẹgbẹ.
Bẹẹ lo ní wọn sì jẹwọ pe awọn mọ nípa iku awọn eeyan meji yi.
- 'Panel Beater' méjì ya odi òjijì lẹ́yìn tí alága ẹgbẹ́ mọkáláìkì tẹ́lẹ̀ gbá wọn l'étí ní Eko
- Taliban gbé òfin kalẹ̀ lórí àwọn Obìnrin atọ́kùn ètò, bó ojú rẹ tóo bá fẹ́ ka ìròyìn bí bẹ́ẹ̀ kọ́.....
- Ẹran màálù N328 bilionu ni àwọn ará Eko ń jẹ ní àárín ọdún kan- ìjọba
- Manchester City gba adé Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti 2021/ 2022
- Ọlọ́pàá ìpínlẹ Ogun mú olùkọ́ tó fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ ọdún mẹ́sàn-án lòpọ̀
- Ìwà aṣemáṣe gbaṣẹ́ lọ́wọ́ dókítà àti nọ́ọ̀sì ní ìpínlẹ̀ Oyo
- Wo bí àwọn agbébọn ṣe pa Okechukwu Okoye, aṣòfin kan ní ìpínlẹ̀ Anambra tí wọ́n sì gé orí rẹ̀ sọnù
- Òkú mẹ́ta, alàyè márùn-ún lá ti yọ nínú ilé tó wó ní Lagos Island
- Fífẹ̀ ju ìyàwó kan lọ ni àṣírí ẹ̀mí gígùn'
Kini ileeṣẹ ọlọpaa Ekiti so?
Adesina, ti alukoro ọlọpaa Ekiti Sunday Abutu, soju fún ṣafihan awọn afurasi yi ati awọn metadinlogun mii fún oríṣi ẹsẹ miran bi ijinigbe ati jiji maalu gbe.
Abutu so pé "Ni nkan bi ago mẹjọ owurọ ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣù kẹrin ni awọn ìkọ wa yabo ibuba awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun nibi ti wọn ti n ṣé Ipade"
O darukọ awọn afurasi naa ti ọwọ tẹ gẹgẹ bi:Alayerogun, Fatoye, Ogunsakin, Oluwadare, Bimbola, Afolabi, Adelola, Ogundola, Adeyemo, Johnson, Kolawole, Babalola, Fanimo, Awoyemi, Charles, Thomas, Obanla ati Anjorin.
O fikun pe awọn ọlọpaa ṣí n tọ ipasẹ awọn to sa ninu wọn.
O daruko awọn nkán ìjà oloro ti wọn ká mọ wọn lọwọ bi ibọn,ada meji, ati awọn alupupu mẹwàá tí wọn fí n ṣe iwa aburú wọn.
Abutu tẹ siwaju pe awọn ọlọpaa tun ri awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun meji mii mu ni ọjọ kẹẹdogun oṣù karun.
O ni wọn ṣe ikọlu s'àwon akẹ́kòó fásítì Ekiti ni ibùgbé wọn tó wà ní Iworoko-Ekiti.
O ni awọn afurasi meji naa Akinbo ati Shodipe jẹwọ pe ọmọ ẹgbẹ Aiye lawon.
Bakan naa ni awọn ọlọpaa ṣe afihan awọn mi to jẹ adigunjalè to lọwọ nínú ikọlu si ile okowo pamọ́ Wema lọdun 2020.
- Ọmọ orílẹ̀-èdè Denmark pa ìyàwó rẹ̀ ọmọ Naijiria àti ọmọ wọn l'Eko, ìjọba dájọ́ ikú nípa yíyẹgi fún un
- Ẹran màálù N328 bilionu ni àwọn ará Eko ń jẹ ní àárín ọdún kan- ìjọba
- "Ogun ló gbé mi lọ sí Central African Republic, àmọ́ ọmọ ni mo gbé bọ̀"
- Fífẹ̀ ju ìyàwó kan lọ ni àṣírí ẹ̀mí gígùn'
- Wo ohun tí iléeṣẹ́ ológun ṣe fun obìnrin yìí lẹ́yìn ọdún Mẹ́tàdínlọ́gọ́rin tí wọ́n gba àkàrà òyìnbó lọ́wọ́ rẹ̀
- Ọlọ́pàá ìpínlẹ Ogun mú olùkọ́ tó fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ ọdún mẹ́sàn-án lòpọ̀
- Òkú mẹ́ta, alàyè márùn-ún lá ti yọ nínú ilé tó wó ní Lagos Island
- Ìdajì ilé mi ni mo tà láti rán ọmọ mi nílé ẹ̀kọ́ àmọ́ wọ́n gbẹ̀mì rẹ̀ láìtọ́jọ́ - Bàbá Deborah Samuel
- Agbẹjọ́rò 34 táa tán nílé ẹjọ́, bí wọ́n ṣe sọ àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú ikú Deborah Samuel sẹ́wọ̀n rèé















