PDP Primaries: Gbọ́ nkán tí ẹgbẹ́ PDP sọ nípa ìròyìn tó gbòde pé ìdìbò owó lọ́wọ́ ẹyìn nílẹ̀ ní wọn n ṣé l'Abuja

Kò sóhun tó ń jẹ́ pẹ́lú dìbò ko sebẹ̀ láàrín àwọn aṣojú-dìbò wa -PDP
Eto idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu PDP lati yan oludije fun eto idibo sipo aarẹ orilẹede Naijiria n waye lọwọ ni gbagede isire indoor sports hall papa isire MKO Abiola nilu Abuja.
Awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP to ba BBC sọrọ ni eto gbogbo ti to fun ayeyọri ẹgbẹ naa ati pe ko ni si wahala lẹyin eto naa.
- Wo àwọn iṣẹ́ méje tí o lè kọ́ láàrín oṣù mẹ́ta ti ASUU da iṣẹ́ sílẹ̀
- Ìdí mọ́kànlá nìyìí tí mo fi fẹ́ díje dupò ààrẹ ní Naijiria – Bukola Saraki
- Óṣe! ènìyàn kan kú ẹlòmíràn farapa bí ọkọ̀ ńlá ṣe jábọ́ léwọn lórí l'Eko
- Fí fún ẹkùn tàbí ẹ̀yà kan ní tíkẹ́ẹ̀tì 'zoning' kò sí nínú òfin ẹgbẹ́ wa - PDP
- Ààrẹ Buhari pàrọwà sí ASUU láti padà sẹ́nu iṣẹ́ nítorí àwọn akẹ́kọ̀ọ́
- Wo àwọn mínísítà ìjọba Nàìjíríà tó ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ nítorí àṣẹ Ààrẹ Buhari
- Mọ̀ síi nípa IPOB tó ń gbé orí ayélujára dá rúgúdú sílẹ̀ nítorí ọ̀rọ̀ Biafra
- Kìí ṣe àwọn mínísítà tó fẹ́ dupò nìkan ní Buhari ní kó fi iṣẹ́ sílẹ̀ , wo àwọn tó tún kàn
- Ọ̀rọ̀ pátà dídọ̀tí tún rúná sí ìjà láàrin Nkechi Blessing àti ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ tẹ́lẹ̀, Falegan
- Èèyàn 60 l'erin ti pa láàrín ọdún yìí nìkan lórílẹ̀èdè Zimbabwe
- Àwọn olùfẹ̀hónúhàn dáná sun dúkìá bí ìwọ́de ṣe ń le si
- Ẹ múra o, ọ̀wọ́n gógó bẹntiró ń rúgbó bọ̀- IPMAN ṣèkìlọ̀ fún àwọn ọmọ Nàìjíríà
Bakan naa ni wọn tun ṣalaye pe awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu naa ko mọ si oro owo re e ibo ree ti iroyin rẹ n kaakiri pe o n waye laarin awọn oludije ati aṣoju lawọn ẹgbẹ oselu lọwọ yii.
Okan lara àwọn ọmọ igbimọ majẹkobajẹ ẹgbẹ naa lati ipinlẹ Ọyọ ṣalaye pe ohun to jẹ awọn Oludije ẹgbẹ oṣelu naa ni lati yan oludije ti yoo ṣoju awọn ọmọ Naijiria ti yoo si mu igba pada si rere fun orilẹede Naijira.
Bakan naa ni aarẹ ile aṣofin agba Naijiria nigba kan ri Sẹnetọ David Mark pẹlu fi gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ PDP lọkan balẹ pe didun lọsan yoo so fun wọn ati pe o da oun loju pe ko ni si wahala, ikunsinu tabi edeaiyed kankan lẹyin abajade idibo naa.

Bakan naa ni gomina ipinlẹ Bayelsa, Duoye Diri pẹlu kin ọrọ naa lẹyin ti wọn si ni eto gbogbo ti to bayii ko si si oun to n jẹ ayipada ọjọ eto naa nitori awọn ti ṣetan bayii.
- Aisha Binani di obìnrin àkọ́kọ́ tó gbégbá orókè láti dupò gómìnà lọ́dún 2023
- Ìdí mẹ́rin rè é tí dọ́là ẹyọ̀kan ṣe di 600 naira ní Naijiria
- Ǹkan tí àwon omo Naijiria ń so nípa ''delegates'' tó ń dìbò fún egbé òsèlú ní yìí...
- Mò ń rí ara mi bíi obìnrin tí kò pé nítorí mi ò lè bí ọmọ láyé - Nse Ikpe-Etim
- Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀tọ̀ lórí àwọn tó pin gàrí, ṣúgà àti mílíkì níbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ
- ''Àwọn adìyẹ tí mò ń sìn ni mo ń fún ní Indian Hemp mu ''
- Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀tọ̀ lórí àwọn tó pin gàrí, ṣúgà àti mílíkì níbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ
- Aisha Binani di obìnrin àkọ́kọ́ tó gbégbá orókè láti dupò gómìnà lọ́dún 2023








