Basorun Akinade Ayoola Yusuf: Ìsìnkú Aláàfin Oyo àti Ooni Ile Ife yàtọ̀ nílẹ̀ Oodua
Ajiṣe bi Oyo laa ri- Basorun Yusuf Akinade Ayoola
Lati igba ti erin Iku Baba Yeye, Oba Lamidi Adeyemi keta ti wo Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo ni awọn eeyan ti n beere ibeere to pọ.
Won n beere lori eto isinku ati ọna isinku Alaafin OyoWo Alàáfin 43 tó jẹ́ láti ìgbà ìwásẹ̀ ṣáajú Lamidi Adeyemi tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wàjà
Eyi lo mu ki BBC Yoruba gbera lọ si Oyo lọ ṣe iwadii to yẹ nipa Abobaku, irufẹ eto isinku ti wọn n sin awon alaafin saaju asiko ayelujara ti a wa yii ati ọna ti wọn n gba fi Oba mii jẹ ni Oyo ile ati Oyo Oko pẹlu pataki awọn Oyomesi.
- 'Aláàfin ti rí ikú rẹ̀ ṣáájú ọjọ́ tó wàjà, ó sọ̀rọ̀ sílẹ̀ kó tó kú'
- Wo àwọn òrékelẹ́wà tí yóò ṣe opó lẹ́yìn Aláàfin Oba Adeyemi tó papòdà
- Ẹ yé fi ìpapòdà àwọn lọ́balọ́ba ìpínlẹ̀ Oyo kọmi lọ́rùn - Gómìnà Seyi Makinde
- "Kòríkòsùn lèmi àti Alaafin ṣùgbọ́n kété táwọn kan kẹ́ẹ́fín pé èmi láàyò ni gbogbo nǹkan dojúrú." Badirat Ajoke, olorì tẹ́lẹ̀ kẹ́dùn Alaafin
- Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn olòrì Alaafin Adeyemi àtàwọn tó bá fẹ́ fẹ́ wọn
- Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi
Kini Basorun Ayoola sọ nipa Eto Isinku Alaafin Atanda Olayiwola?
Basorun Yusuf Akinade Ayoola ṣalaye fun BBC Yoruba pe ki gbogbo araye le rii pe ara Alaafin Lamidi Adeyemi keta ni wọn fẹ lọ sin ni wọn ṣe gbe e sita.
O ni ki wọn le mọ pe o gbagbọ naa si ni Oyomesi ṣe jẹ ki awọn elesin Islam wẹ Oba Lamidi ki wọn si kirun si Iku Baba Yeye.
O ni pe ni kete ti awọn Musulumi kirun si alaafin tan naa ni awọn si ti gbe ara Alowolodu wọ aafin lọ lati fi yanju eto to ku.'Ètò ayẹ́yẹ́ ìsìnkú Oba Lamidi Adeyemi kòí tíì wáyé, àfọ̀mọ́ Aàfin ń lọ lọ́wọ́'

- Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii
- Àwọn jàǹdùkú sọ àjọ̀dún Amole di 'ọdún olè jíjà' nílùú Akure
- Àwọn oúnjẹ ilẹ̀ Yorùbá ní à ń kọ nínú Akọ́mọlédè àti Àṣà lónìí
- Mọ̀ sí i nípa Oba Yesufu Asanike, Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- Ṣé ìwọ mọ ìtàn Ibadan àti ìgbín mẹ́rin? ipá wo ni Abuké àti Àfín kó nínú ìtàn Ibadan?
- Wo àwọn ǹkan tí o kò mọ̀ nípa Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò tó wàjà
Wo ìtàn ọmọ Olokunẹṣin tí wọ́n jẹ́ Abọ́bakú gbogbo Alaafin lati iran de iran:
Olootu Oyomesi, Basorun Yusuf Ayoola ṣalaye ni kikun lori ohun to ṣokunfa Abobaku ni aafin Oyo bẹrẹ lati ọdọ àwọn Alaafin to ti lọ darapọ mọ awọn Alaseku.
Bakan naa ni O tun sọ nipa idile Olokunẹsin to n jẹ Abobaku fun gbogbo Alaafin Oyo lati igba iwase.
O pari rẹ pe, eto Abobaku ti pari ni Oyo, ati pe, ẹni to yẹ ko ba alaafin Lamidi Adeyemi rin lasiko yii ṣi wa laaye ati ni alaafia.Ta ni Yorùbá ń pè ní Abọ́bakú?
- Ọ̀pẹ́lọ̀pẹ́ Olorì Ladun aya Ooni Sijuwade ni mo fi gba òmìnira tí mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Olorun- Abobaku Ooni Sijuwade
- Baba Latin ṣe bẹbẹ lórí ètò Sé o láya?, sùgbọ́n...
- Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
- Wòlíì ní ọmọ táà bá bí ni ago kan géérégé ni...Bàbá tó bí Ooni Adeyeye Ogunwusi sọ àṣírí àkọsẹ̀jayé rẹ̀
- Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Ìjálá, Ìrèmọ̀jé àti oríkì ọ̀pọ̀ ẹranko ijù
Mọ̀ síi nípa owé: Ajiṣe bi Oyo làá rí.......
Basorun ilu Oyo sọrọ ni kikun pe gbogbo nkan nipa Oyo lo yatọ.
O ni pe ilu Oyo ile ati Oyo Oko to gbe Oyo duro lonii ni eto, aṣa, iṣeṣe a[ti igbagbọ ninu awọn Alalẹ.
O sọ idi ti wọn ko ṣe sin Oba ni oku oru rara.
- 'Gbogbo ìgbà ti mo bá rántí bí Táyà Tírélà ṣe gé ọwọ́ èmi àti ọmọ, tí ẹsẹ̀ rẹ̀ bàjẹ́, ojú mi fọ́...'
- Ìdí tí wọn kii fi jẹ́ kí obìnrin jẹ Ọ̀ọ̀ni ni Ile Ife
- Kí lo mọ̀ nípa ìgbeyàwó Àbẹ̀ẹ́lẹ̀, Àṣàǹte, Ọkọ Káalẹ́ àti Gbàmí o ràmí?
- Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo
- Wo ìtàn ọgọ́ta ọdún Nàíjíríà nínú àwòrán mẹ́fà péré
- Báyìí ni Egúngún àti Orò ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba
- Àwọn Oba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí Oba míràn jẹ lójú ayé wọn

Oríṣun àwòrán, Others
Ta ló maá dé adé Alaafin Oyo lẹ́yìn Oba Lamidi Adeyemi?
Basorun to jẹ ọlọwọ ọtun Alaafin to tun jẹ olori adari Oyo lati igba ti Oba Lamidi Adeyemi ti waja ti sọrọ lori ẹni ti ade kan lati de.
Basorun Ayoola sọ fun BBC Yoruba pe titi di ilẹ to mọ loni yii, Gbogbo Oyo nile, loko ati lẹyin odi koi tii mọ ẹni ti yoo jẹ Alaafin.

O ni eyi ko ṣeyin pe Oyo ti mọ idile to kan nitori pe, Itọsẹ lo ni Oyo
Ati pe wọn ti mọ igbesẹ aṣa ati Ifa ati bi ọrọ ṣe maa ri ṣugbọn kosi kanjukanju ninu yiyan Alaafin tuntun.
- Wo ilé Adebisi Idikan n‘Ìbàdàn, àwòdamiẹnu ni
- Agbọ́nmágbọ́ntán, Agọ̀mágọ̀jù, mọ̀ síi nípa àwọn orúkọ Ìjàpá nínú alọ àpagbè Yorùbá
- ìdí tí mi ò lè fi àṣà Yorùbá àti ọ̀rọ̀ Ifá sílẹ̀ títí d'ọjọ́ alẹ́ rèé - Jimi solanke
- Títí di bí a ṣe ń sọ̀rọ̀ yìí, èmi gan an kò mọ irú ẹni tí Wole Soyinka jẹ́- Ojọ̀gbọ́n Wole Soyinka
- Wo ọ̀nà àrà àti ẹ̀fẹ̀ tí Yorùbá fi ń polówó ọ̀jà láyé àtijọ́ àti òde òní
- Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni

Oríṣun àwòrán, Oyo Archive