Femi Falana: Ọwọ́ tí Buhari fi mú mú ọ̀rọ̀ Kanu àti Igboho jọ èyí tí wọ́n fi mú olóṣèlú kan lọ́dún 1984

Oríṣun àwòrán, Cool FM 96.9 Kano
Ajafẹtọ ọmọniyan ati agbẹjọro agba, Femi Falana ti sọ pe awọn igbesẹ ti Aarẹ Naiijiria n gbe yoo da Naijiria pada si ọdun 1984, ṣugbọn awọn araalu ko ni gba fun.
Falana lo sọ ọrọ naa nibi ijiroro kan lati sami si ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mẹ́tàdínláàdọ́rùn ún Ọjọgbọn Wole Soyinka loke eepẹ.
Agbẹjọro naa ṣo pe ọwọ ti ijọba Buhari fi mu ọrọ Nnamdi Kanu ati Sunday Igboho farajọ eyii ti wọn lo lati fi ji oloṣelu kan gbe lọdun 1984.
- Oríire ńlá ló jẹ́ fún àwọn ọmọ Naijiria pé orílẹ̀-èdè yìí ṣì wà ní ọ̀kan ṣoṣo- Buhari
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
- Gbẹgẹdẹ gbiná, ṣọ́jà àtàwọn jàǹdùkú fìjà pẹẹ́ta lọ́jà Ladipo l'Eko
- Mọ si nípa àbá òfin tí yóò mú kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti le gbẹ́sẹ̀ lé ilé tàbí ilé ìtura tí ífipá bálòpọ̀ bá ti wáyé
- Ó kéré tán, ajínigbé ti pa èèyàn 222 láàrìn oṣù mẹ́ta ní Kaduna- Gomina El Rufai
- Ọkùnrin márùn-ún tí wọ́n bá lórí kerewà bọ́ sọ́wọ́ Ọlọ́pàá ẹ̀sìn Islam
O ni "Ko yẹ ki a gba Buhari laaye lati da wa pada si ọdun 1984 bii igba ti wọn gbiyanju lati ji Umaru Diko gbe ni London."
"Wọn ti ji Diko gbe tan lọdun naa lọhun, ṣugbọn ara adugbo kan lo figbe ta lasiko ti wọn n gbe lọ si papakọ ofurufu."
Falana ṣalaye pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ṣe ni wọn kun Nnamdi Kanu loorun ki wọn to gbe wa si Naijiria nitori ijọba Kenya ko le ṣalaye pe awọn finu-findọ fa Kanu le ijọba Naijiria lọwọ.
O ni irọ ni awọn to sọ pe ọna to ba ofin mu ni wọn fi gbe Kanu wa si Naijiria n pa.
Ajafẹtọ naa fikun pe eremọde lasan ni awọn to ni ki awọn araalu má ṣe ifẹhonuhna n sẹ nitori ironu awọn ologun lo wa ninu ọpọlọ wọn.
O sọ siwaju si pe Buhari ti gbagbe pe awọn ti gbe Aarẹ Olusegun Obasanjo lọ sile ẹjọ lọdun 2003 ri, lẹyin ti Obasanjo tu iwọde kan ti Buhari ti kopa ka, ti Buhari si jare lati ile ẹjọ ọhun.
- Mr. Portable sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Mr. Latin lórí gbas-gbos tó ń wáyé lágbo òṣèré tíátà Yoruba
- Gbàgbé ẹ! Ìjọba kò lè yọwọ nínú fifi ọba jẹ láéláé- Oba Tejuosho
- Àwọn Aṣòfin yọwọ́ nínú àbádòfin tí yóò máa fòfin de àwọn akọ̀ròyìn lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀hónúhàn
- Ìjọba Gombe kọ́ iléẹ̀kọ́ tuntun sí ẹgbẹ́ àwọn iléeṣẹ́ elétò aàbò kí ọwọ́ ajínigbé má tẹ̀ akẹ́kọ̀ọ́ mọ́
O ni ile ẹjọ naa sọ pe ko ba ofin mu ki eeyan kọkọ lọ gba iwe aṣẹ lọwọ ọlọpaa ko to ṣagbatẹru iwọde tabi kopa ninu iwọde kankan, ati pe awọn eeyan to ti gba ominira ko nilo iwe aṣẹ ọlọpaa kankan ki wọn to ṣe iwọde.
Falana ni eredi ree ti awọn fi gbogun ti ile igbimọ aṣofin lati ṣe ofin tuntun kan to sọ pe awọn araalu ko nilo lati fi to ileeṣẹ ọlọpaa leti ki wọn to ṣe iwọde, ayafi ki wọn wa pese eto abo fun wọn, kii ṣe lati gba aṣẹ.
- Wọ́n ní Ìyá Esabod yẹn ma ń ṣépè, fi òṣèré wọ́lẹ̀, mò ń retí èsì yín sí ọ̀rọ̀ tí mo fi síta yìí - Mr Portable
- Mọ si nípa àbá òfin tí yóò mú kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti le gbẹ́sẹ̀ lé ilé tàbí ilé ìtura tí ífipá bálòpọ̀ bá ti wáyé
- Kò sọ́jà mọ́! A ti ti Ọjà Ladipo pa nítorí rògbòdìyàn tó bẹ́ sílẹ̀ níbẹ̀ - `ijọba ìpínlẹ̀ Eko
- Oríire ńlá ló jẹ́ fún àwọn ọmọ Naijiria pé orílẹ̀-èdè yìí ṣì wà ní ọ̀kan ṣoṣo- Buhari
- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin tó gbé ọ̀kadà iléesẹ́ sá lọ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́



















