Igboho, Akintoye, Yoruba Nation pe ẹ̀sùn mọ́ Buhari, Malami àtàwọn míì ní Kóótù `ọdaràn `Agbáyè, ICC

Oríṣun àwòrán, Atlantic Council
Ẹsun ipaniyan ati ifiyajẹ ọmọ eniyan ni wọn fi kan aarẹ Buhari ati Malami pẹlu bi wọn ṣe pa lara awọn ajijagbara fun Ilẹ Yoruba ati awọn miran.
Ileẹjọ to n gbọ ẹsun iwa ọdaran lagbaye, ICC ti fi lede pe awọn ti gba iwe ẹsun ti adari Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua, Ọjọgbọn Banji Akintoye, Sunday Igboho ati awọn ajijagbara mọkandinlaadọta miran pe mọ ijọba Naijiria ati awọn adari.
Ile ẹjọ ICC ti fi atẹjade sita pe wọn ti bẹrẹ iwadii nipa ẹjọ naa bayii.
- Ọkùnrin márùn-ún tí wọ́n bá lórí kerewà bọ́ sọ́wọ́ Ọlọ́pàá ẹ̀sìn Islam
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
- Ó kéré tán, ajínigbé ti pa èèyàn 222 láàrìn oṣù mẹ́ta ní Kaduna- Gomina El Rufai
- Ohaneze Ndigbo lẹ́tọ̀ọ́ láti gba agbẹjọ́rò fún Nnamdi Kanu- Malami
- Àwọn Aṣòfin yọwọ́ nínú àbádòfin tí yóò máa fòfin de àwọn akọ̀ròyìn lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀hónúhàn
- 'Lóòtọ́ èmi ni mo ṣagbátẹrù òpó alátagbà Airtel lọ sí Ago Owu ṣùgbọ́n kìí ṣe àkànṣe iṣẹ́ agbègbè mi'
- Ìjọba Gombe kọ́ iléẹ̀kọ́ tuntun sí ẹgbẹ́ àwọn iléeṣẹ́ elétò aàbò kí ọwọ́ ajínigbé má tẹ̀ akẹ́kọ̀ọ́ mọ́

Oríṣun àwòrán, @TheNationNews
A ti gba ẹ̀sùn tí ẹ fi kan Buhari, Malami, Buratai wọlé - Kóótù `ọdaràn l'ágbáyè, ICC
Ẹjọ naa ni wọn pe mọ Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari , minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami, adari ikọ ọmọogun Naijiria, Tukur Buratai ati ọga ọlọpaa agba tẹlẹri, Ibrahim Idris ati Muhammadu Adamu.
Lara awọn adari miran ti wọn pe ni ẹjọ ni Hammid Alli, Alkali Baba, Farouk Yahaya, Sadiq Abubakar, Ahmed Abubakar Audi, Mohammed Babandede ati Abdulahi Gana Muhammadu.
Ṣaaju lỌjọru ni Sunday Igboho, Akintoye àtàwọn míràn fa Buhari, Malami àtàwọn míì lọ síwájú ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC
- Sunday Igboho, ṣe sùúrù díẹ̀ lórí ìwọ́de Yoruba Nation l‘Eko - Olugbon ń lọgun
- Ìbọn àti nǹkan ìjagun ni Igboho kó pamọ sílé ló jẹ kí á yabo ilé rẹ̀ - DSS
- Wọ́n ní Ìyá Esabod ma ń ṣépè, fi òṣèré wọ́lẹ̀, mò ń retí èsì yín sí ọ̀rọ̀ tí mo fi síta yìí - Mr Portable
- Ó kéré tán, ajínigbé ti pa èèyàn 222 láàrìn oṣù mẹ́ta ní Kaduna- Gomina El Rufai
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
Ninu atẹjade ti ileẹjọ ICC lagbaye fi ṣọwọ pada si wọn ni wọn ti fi lede wi pe awọn ti bẹrẹ iwadii lori ẹsun ti wọn fi kan awọn adari yii ni ẹyọ kọọkan.
Ẹsun ipaniyan ati ifiyajẹ ọmọ eniyan ni wọn fi kan aarẹ Buhari ati Malami pẹlu bi wọn ṣe pa lara awọn ajijagbara fun Ilẹ Yoruba ati awọn miran.
Bakan naa ni wọn fẹsun kan awọn wọnyii pe wọn lọwọ ninu ọrọ ipaniyan, dida awọn ọmọ Naijiria pada lati oke okun lọna aitọ.
Lara ẹsun ti wọn tun fi kan wọn ni ifiyajẹ ọmọniyan lọna aitọ, ijinigbe ati ifipabanilopọ eleyii ti wọn ko ri iru rẹ ri.
- Ẹ̀ṣọ́ ìyàwó Gómìnà Ekiti Bisi Fayemi bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ l'Abuja
- Sunday Igboho, Akintoye àtàwọn míràn fa Buhari, Malami àtàwọn míì lọ síwájú ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC
- Oríire ńlá ló jẹ́ fún àwọn ọmọ Naijiria pé orílẹ̀-èdè yìí ṣì wà ní ọ̀kan ṣoṣo- Buhari
- Mo gbọ́ pé babaláwo mẹ́ta ló tẹ̀lé àwọn DSS lọ sí ilé Sunday Igboho- Gani Adams
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
- Gbẹgẹdẹ gbiná, ṣọ́jà àtàwọn jàǹdùkú fìjà pẹẹ́ta lọ́jà Ladipo l'Eko
















