Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó yẹ lórí ọ̀dọ́ ni- Oladosu Fatomilola
Nitori pe ijọba ati Obi ti kuna lori iṣẹ rẹ lori ọdọ ni wọn ṣe n ronu lọ si idi ṣiṣe Yahoo- Oladosu Fatomilola.
Oladosu Fatomilola Ọmọ gbajugbaja oṣere ni, Peter Fatomilola ti ṣalaye siwaju sii lori ọrọ baba rẹ pé Mo fẹ́ kí a dá Yorùbá Nations sílẹ̀ kí a lè máa mójútó àwọn adarí tó bá kọsẹ́ fúnra wa- Peter Fatomilola.
O ni awujọ wa ti kuna, ijọba ti kuna, Obbi ti kuna, ile ijọsin ti kuna, koda, alagbatọ ti kuna lati tọ awọn ewe ati ọdọ wa bi o ti yẹ.
- A ti gba ẹ̀sùn tí ẹ fi kan Buhari, Malami, Buratai wọlé - Kóótù `ọdaràn l'ágbáyè, ICC
- Wọ́n ní Ìyá Esabod yẹn ma ń ṣépè, fi òṣèré wọ́lẹ̀, mò ń retí èsì yín sí ọ̀rọ̀ tí mo fi síta yìí - Mr Portable
- Oluwo àti Oba Kuta nìkan ló tíì jáde lòdì sí Oduduwa Republic, àwọn Ọba tó pọ̀ wà lẹ́yìn wa lábẹ́nú- Iba Gani Adams
- 'Restructuring' la fi ta Buhari fún ìran Yorùbá, ṣùgbọ́n ó dùn mi pé irọ́ ni Buhari pa- Olagunsoye Oyinlola
- Títí di bí a ṣe ń sọ̀rọ̀ yìí, èmi gan an kò mọ irú ẹni tí Wole Soyinka jẹ́- Ojọ̀gbọ́n Wole Soyinka
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
- Èèyàn 2,371 ni wọ́n jí gbé, N10biliọnu owó ìtúsílẹ̀ làwọn ajínigbé gbà lóṣù mẹ́fà àkọ́kọ́ ọdún 2021
- Gbàgbé ẹ! Ìjọba kò lè yọwọ nínú fifi ọba jẹ láéláé- Oba Tejuosho
- Àfinra! Ẹ wá máa lọ ilé ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́ títí di ọjọ́ wájú, a ti ti ìbugbé ilé ẹkọ́ pa torí Covid-19 - Fásitì Unilag
Oladosu Fatomilola ṣalaye pe bi awa kan se fara mọ ọrọ naa ni awọn mii ni o dara ki awọn ọm Yoruba maa gba owo ti iran oyinbo jẹ babanla Yoruba.
O mẹnuba bi ijọba se kuna ni eyi ti o fi di isoro airi iṣẹ ṣe fun awọn ọdọ.
- Ọkùnrin márùn-ún tí wọ́n bá lórí kerewà bọ́ sọ́wọ́ Ọlọ́pàá ẹ̀sìn Islam
- 'Lóòtọ́ èmi ni mo ṣagbátẹrù òpó alátagbà Airtel lọ sí Ago Owu ṣùgbọ́n kìí ṣe àkànṣe iṣẹ́ agbègbè mi'
- Mọ̀ síi nípa Ibeju Lekki nípinlẹ̀ Eko níbí tí wọn kò tí ní iná Mọ̀nàmọ́ná fún ogún ọdún tí Bàálẹ̀ ti ń fa 'Generator'
- Sunday Igboho, Akintoye àtàwọn míràn fa Buhari, Malami àtàwọn míì lọ síwájú ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC
- Chidinma ò gbudọ̀ kú o sátìmọ́lé Ọlọ́pàá o! Àwọn aṣòfin f'ọ̀rọ̀ ráńṣẹ́ sí Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá
- Ohaneze Ndigbo lẹ́tọ̀ọ́ láti gba agbẹjọ́rò fún Nnamdi Kanu- Malami
Oladosu gba awọn ọdọ ilẹ Yoruba niyanju lati tubọ tẹpa mọ iṣẹ ọwọ wọn nitori pe atẹlẹ ẹni kii tan ẹni jẹ ati pe ọjọ ti a ba gun kọ ni a n kan ọrun.
Bakan naa lo gba awọn Obi ati Alagbatọ lati tọ awọn ọdọ iwoyi sii nipa iwa ọmọluwabi eyi ti ṣiṣe gbajuẹ ati Yahooyahoo ko si nibẹ rara.
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
- Èèyàn 2,371 ni wọ́n jí gbé, N10biliọnu owó ìtúsílẹ̀ làwọn ajínigbé gbà lóṣù mẹ́fà àkọ́kọ́ ọdún 2021
- Àwọn Aṣòfin yọwọ́ nínú àbádòfin tí yóò máa fòfin de àwọn akọ̀ròyìn lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀hónúhàn
- Oríire ńlá ló jẹ́ fún àwọn ọmọ Naijiria pé orílẹ̀-èdè yìí ṣì wà ní ọ̀kan ṣoṣo- Buhari
- Ìjọba Gombe kọ́ iléẹ̀kọ́ tuntun sí ẹgbẹ́ àwọn iléeṣẹ́ elétò aàbò kí ọwọ́ ajínigbé má tẹ̀ akẹ́kọ̀ọ́ mọ́