Peter Fatomilola: Àsìkò ti tó kí ìpinyà wa, kí kaluku mójútó ọ̀rọ̀ ajé rẹ̀- Peter Fatomilola
Owó táwọn Òyìnbó jẹ Babańlá Yorùbá ní àwọn ọmọ Yahoo-yahoo ń gbà padà- Peter Fatomilola
'Robbery' burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba wọn padà lọ́wọ́ Oyinbo amúnisìn
Oyinbo ko iran baba nla Yoruba lẹru fun ọdun 500 pélu ọpọlọpọ iya- Peter Fatomilola
Agbaọjẹ oṣere ati olukọ Yoruba, Alagba Peter Fatomilola lo sọrọ nipa awọn ọmọ Yahoo ati ọrọ ki Yoruba da duro.

Oríṣun àwòrán, @Fatomilola
O ni iṣẹ ọpọlọ lawọn ọmọ Yahoo n ṣe lati gba owo ti iran oyinbo jẹ baba nla iran Yoruba ti wọn ko lẹru.
O ni ọmọ Yoruba ko ṣa a deede maa ṣe yahoo. airise se lo n fa a.
Fatomilola ni Obi. alagbatọ ati Ijọba lo fa ohun to n sun awọn ọdọ si iṣẹ yahoo.
- Yinka Alaṣeyori fi ọ̀rọ̀ ìjínlẹ̀ púpọ̀ àiti omijé ṣàlàyé Oniduro Mi
- 'Òògùn ìtọ́jú egbò ni Musa pe àgbo tó fún mi, àmọ́ èèyàn mẹ́wàá ti kú lẹ́yìn tí wọ́n lò ó'
- Lẹ́yìn ìjà tò gbẹ̀mí èèyàn bíi mẹ́ta, Makinde sè ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ àlákòóso Amọtẹkun
- Ọ̀run àpáàdì ń dúró de gbogbo ẹ̀yin aláìní ìrònúpìwàdà- Fani Kayode sí Gumi
- A kò gbọ́ pé Sunday Igboho fẹ́ ṣe ìwọ́de ní ìpínlẹ̀ Eko- Kọmisọ́nnà ọlọ́pàá
- Àwọn Bòròró agbébọn ló pa Fulani ọmọ mi, a kọlù wọ́n lá fi rí eèyàn méjì gbà nínú àwọn tí wọ́n jígbé ní Ajowa-Baba Fulani
- Ṣé lóòtọ́ ni olè kan wọlè fipá bá ìyá 80 lòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ondo?
Peter Fatomilola ni gbogbo ọna loun fi faramọ 'Yoruba Nation'
O ni ko si ohun to buru ninu ti iran Yoruba, Igbo ati Hausa ba ni ki onikaluku lọ da ọmọ iya ẹ gbe.
O ni ti onikaluku ba pin lọtọọtọ, ẹnu a ka awọn adari wa, a maa le fẹnuko ba wọn wi.
- A ti fi páńpẹ́ ọba mú ènìyàn mẹ́ta lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Iwo Road, Ibadan - Ọlọ́pàá
- Alága ìjọba ìbílẹ̀ Eti-Osa, Eko tí jádé láyé lẹ́yìn tó ṣe àìsàn
- Kò sí ìpínlẹ̀ tí ijọba mi kò tíì fọwọ́ bà sí rere- Ààrẹ Muhammadu Buhari
- Ẹranko àìmọ́ kan wọ Nàìjíríà, ó pa ènìyàn mẹ́rin ní Benue- ilé iṣẹ́ ọmọogun ni ìròyìn òfegè ni
- Pipa ní wọ́n gbọ́dọ̀ pa àwọn agbébọn tí wọ́n ń jí àwọn ènìyàn gbé, ẹ da ọ̀rọ̀ Sheik Gumi nù -Aisha Yesufu
- Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́...- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ibadan
- Lẹ́yìn ìjà tò gbẹ̀mí èèyàn bíi mẹ́ta, Makinde sè ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ àlákòóso Amọtẹkun
Lori ọrọ Sunday Igboho:
Sunday Igboho kii ṣọmọ ale rara ni Peter Fatomilọla fi bẹrẹ ọrọ lori ọrọ Sunday Igboho ti apeja rẹ n jẹ Oloye Sunday Adeyemọ.
Peter Fatomilola ni gbogbo ara ni oun fi faramọ ijijangbara awọn akoni ọdọ Yoruba bii Sunday Igboho.

Oríṣun àwòrán, @fatomilola
Peter Fatomilola ni igba gbogbo ni oun maa n gbadura fun Sunday Igboho nitori pe Yoruba Nation se koko bayii.
O ni ki a kọkọ ja fun orilẹ-ede ti wa ki a to maa yanju ọrọ tani yoo ṣe olori orilẹ-ede Yoruba Nation.
- Ẹranko àìmọ́ kan wọ Nàìjíríà, ó pa ènìyàn mẹ́rin ní Benue- ilé iṣẹ́ ọmọogun ni ìròyìn òfegè ni
- Pipa ní wọ́n gbọ́dọ̀ pa àwọn agbébọn tí wọ́n ń jí àwọn ènìyàn gbé, ẹ da ọ̀rọ̀ Sheik Gumi nù -Aisha Yesufu
- Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ń kí Kemisola kú oríire ìkómọjáde ọmọ tó bí sọ́gbà ẹ̀wọ̀n lónìí
- Ilé ẹjọ́ ECOWAS pàṣẹ fún Naijiria láti gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó fi de Twitter
- Iléẹjọ́ tí dá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ OPC tó mú Iskilu Wakili sílẹ̀ pé kí wọ́n máa lọ ní àlááfíà

Oríṣun àwòrán, others



