End SARS, Kemisola Oguniyi: Láti 23/10/2020 ni Kemisola Ogunniyi ti dèrò ẹ̀wọ̀n nítorí ìwọ́de EndSARS tó fi wa bímọ sẹ́wọ̀n báyìí
Agbẹjọro Kemisola salaye ibi ti ọrọ de duro bayii.

Omodebinrin Kemisola Oguniyi ti ọwọ awọn agbofinro tẹ ninu iwọde EndSARS ni Ondo ti bimọ si ahamọOlùwọ́de EndSARS bímọ tuntun nínú ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó ti lo oṣù mẹ́jọ ní àhámọ́.
Kemisola ni wọn mu lọjọ kẹtalelogun, osu kẹwaa, ọdun 2020 nibi iwọde EndSARS ti awọn ọdọ ṣe tako ifiyajẹni lọna aito awọn ọlọpaa Naijiria.
- Ìròyìn ikú nípa Prophet SK Abiara; Ẹlẹ́jẹ̀ ni, ohun tí ẹbí Abiara sọ fún oníròyìn náà rèé
- 'Kò sí ẹni tó lè ní kí a má wá sí Èkó, iwọ́de òní pẹ̀lẹ́ kùtù la fẹ́ ṣe'
- Gómìnà ṣàbẹ̀wò sí àwọn tí ọlọ́pàá yìnbon lù l'Enugu, Ọ̀gá ọlọ́pàá ní ìwádìí gbọdọ̀ wáyé kíákíá
- Mo kú tì, nítorí pé àsìkò mi kòì tó láti padà sí ọ̀run- Kunle Ologundudu
- Mọ̀ si i nípa ìtàn eégún Gelede àti pàtàkì eégún náà sí àwọn obìnrin nílẹ̀ Yoruba
- Ṣé lóòtọ́ ni ilẹ̀ America ti bẹ̀rẹ̀ 'visa lottery padà fún àwọn ọmọ Naijiria? Wo àlàyé níbí
- Rahmon ń múra láti lọ rí ìyàwó àti ìbèjì tó bí ní US ni wọ́n bá pa á níbi ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ ní Iwo road
- Kò lè sí ààbò fún iléèwé kankan àfi tí ìjọba bá wá iṣẹ́ fáwọn tó ń jí ọmọ gbé - Gumi

Ninu ẹwọn ni Iya Kemisola ni pe oun ti gbọ pe ọmọ oun wa ni ipo iloyun.
Felicia Ogunsola pẹlu omije salaye gbogbo igbesẹ ti oun ati ọkọ rẹ ti gbe lori irinajo Kemisola yii pe ko le jade kuro latimọle.

Baba Kemisola ti ta ogún ìní rẹ̀ pe kí Kemi lè jáde kuro lẹ́wọ̀n lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS láti 2020.
Oluyemi Fasipe to jẹ aṣoju EndSARS panel ni Ondo naa sọ ero tire pe o ṣoro lati ni pe ọmọdebinrin yii lọ ba nkan jẹ ko dẹ tun fi wa lẹwọn lati iye ọjọ yii wa.
O mẹnuba agbara ofin ati ohun to n ṣẹlẹ bayii

Amofin Tope Temokun to n ṣoju fun Kemisola Oguniyi naa ba BBC Yoruba sọrọ.
O ni ṣe ọmọ tuntun ti Kemi bi lẹ́wọ̀n naa jẹbi iwọde EndSARS ni?
Amofin Tope royin awọn igbesẹ ti wọn ti gbe lati rii pe Kemi kuro lẹwọn ko to bimọ ati bayii to ti bimọ sẹwọn.

Amofin naa fi igbagbọ rẹ han pe, Kemi a jade lẹwọn loni ọjọ Aje kuro ni atimọle ni Ondo.
Gbogbo bi iroyin naa ba se n lọ ni BBC Yoruba yoo maa mu wa fun un yin.
- 'Ẹ̀rú bà mí lọ́jọ́ tí mo wọ bọ́ọ̀sì dẹ́rẹ́bà ọlọ́wọ́ kan lọ Ilorin', ìrírí àwọn èrò ọkọ̀ rèé
- Bola Are kẹnu bọ ọ̀rọ̀ lórí àwọn èdè orin àti ìhùwàsí àwọn Olórin ẹ̀mí lóde òní
- Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
- 'Ẹ má gbọ́kàn lé ewé o, ẹ má gbọ́kàn lé oṣo tàbí àjẹ, Ọlọrun nìkan ni “Oniduro wa!'
- Timothy Obadare ìránṣẹ́ Ọlọ́run to fọ́ lójú ìta ṣùgbọ́n tó ríran jù ọ́pọ́ wòlíì lọ