Fulani attack, Ajowa Ondo: Àwọn Bororo yìí ti kọ́kọ́ ń dàná gba owó ní Ajọwa tẹ́lẹ̀, ọmọ mi 5 di aláìníbaba- Idowu ìyàwó Fulani
Àwa Fulani mọ̀ pé ǹkan tí wọ́n ń se kò dára ṣùgbọ́n...- Baba Fulani
Idowu to jẹ iyawo ọkunrin Fulani ti wọn ṣapejuwe pe o ni suuru lo ba BBC Yoruba sọrọ lori bi nkan naa se ṣẹlẹ.
Saaju ni Toyin Osuolale ti salaye pe awọn bororo yii ti maa n da ọna gba owo lọwọ awọn ara ilu Ajowa nipinlẹ Ondo tẹlẹ.
- Ọwọ́ tẹ ọmọdébìnrín tó jí ara rẹ̀ gbẹ́ nítorí ìyá rẹ̀ ní kó lọ kọ́ ẹ̀kọ́ láti ṣe dókítà
- Ajínigbe sún gbàgbé láwọn 15 nínú àwọn 156 tí wọ́n jí gbé ní Tegina bá sálọ
- Dino Melaye fi ọkọ Rolls Royce bùgá lórí Instagram, ni oníṣòwò ọkọ́ bá ní kó wá san gbèsè owó ọkọ̀ tó jẹ́ òun
- Ẹ wo ohun tí a mọ̀ nípa bí agbébọn ṣe gbẹ̀mí sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀, Titus Badejo Ejanla ní ìlú Ibadan
- Ṣé lóòtọ́ ni àwọn ọmọ ogun òfurufú Nàìjíríà ṣèèṣì pa máàlú 1,000 ní Nasarawa?
- Kemisola jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbé e- Ìyá Kemisola
Wọn ni saa deede ni awọn agbebọn naa ya wọ ilu Ajowa ni agbegbe Oba Akoko nipinlẹ Ondo ni guusu NAijiria.
Nibẹ ni wọn ti pa ọkunrin Fulani kan ti ọpọ maa n pe ni Babatunde Fulani.

Idowu to jẹ aya rẹ ni abẹ bẹẹdi ni oun ni lati ko awọn ọmọ marun un ti oun bi fun Babatunde Fulani pamọ si nitori ojo ọta ibọn to n rọ.
Nilu Ajowa lọsẹ to kọja yii ni wọn ti pa Fulani kan ti wọn si ji awọn mii gbe.
- Kemisola jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbé e- Ìyá Kemisola
- Wo ǹkan méje tí o lè má mọ̀ nípa Fola Alade to ya ilé '1004 Estate' tó dolóògbé
- Wo ìdí tí EFCC fi fẹ́ wádìí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun láti ọdun 2015 dí àsìkò yìí
- Father's Day fa gbas-gbos láàrin Mercy Aigbe àti ọkọ rẹ̀ tẹ́lẹ̀, Gentry, ọkọ́ ní òun le tú àwọn àṣírí ìwà nọ̀bì rẹ̀ síta
Toyin Osuolale, agba baba tọrọ naa kan salaye fun BBC pe nitootọ Bororo ni wọn ti wọn si gbọ Hausa daadaa.
O ni ọpẹlọpẹ Amotekun, Ọdẹ ilu, Agbofinro ati Soja lo ran wọn lọwọ lati lepa awọn Bororo naa.

O ni: Awa Fulani naa mọ pe nkan to n ṣẹlẹ yii ko dara, a ti gbe awọn igbese eto aabo kọọkan ṣugbọn iṣẹ pọ lọwọ ijọba.
Baba Osuolale ni pe awọn ba wọn ti wọn si koju ara wọn ki wọn to ri eeyan meji gab pada ninu awọn ti wọn jigbe ni Ajowa.
- A kò gbọ́ pé Sunday Igboho fẹ́ ṣe ìwọ́de ní ìpínlẹ̀ Eko- Kọmisọ́nnà ọlọ́pàá]
- Ó yẹ kí ìjọba wá ǹkan fi tan àwọn ajínigbépawó, ǹkan bíi owó, iṣẹ́ àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ
- Lẹ́yìn ìjà tò gbẹ̀mí èèyàn bíi mẹ́ta, Makinde sè ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ àlákòóso Amọtẹkun
- 'Kò sí ẹni tó lè ní kí a má wá sí Èkó, iwọ́de òní pẹ̀lẹ́ kùtù la fẹ́ ṣe'
- Ìgbẹ́jọ́ Kemisola Ogunniyi kò wáyé lóní, ó tún dọ̀la, ṣùgbọ́n... - Agbẹjọ́rọ̀
- Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
Eni ti ìṣẹlẹ naa ṣoju rẹ, Oludofin Yekini naa sọ ohun ti oju awọn eniyan Ajowa ni Oba Akoko naa ri lori iṣẹlẹ naa.
Otitoju Ayodeji to jẹ Kansilọ ibi ti ọfọ naa ti ṣe parọwa sijọba lati dide si eto aabo ni Naijiria ni eyi to ti n gba ẹbọ lọwọ koowa bayii..
O ni ko si ẹni to le sọ nipato iye ẹmi ti wọn ti pa ni Akoko bayii.
