Kebbi kidnap, Nigeria Army: Mo ṣetán láti wọ inú igbó lọ wa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé- Gomina ìpínlẹ̀ Kebbi

Oríṣun àwòrán, Facebook/Prounitate
Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
Ileeṣẹ ologun ilẹ̀ Naijiria ti kede pe wọn ti ri mẹrin ninu olukọ ati akẹkọọ pada.
- Ìgbẹ́jọ́ Kemisola Ogunniyi kò wáyé lóní, ó tún dọ̀la, ṣùgbọ́n... - Agbẹjọ́rọ̀
- Àlàyé rè é lórí bí o ṣe lè gbá owó ìrànwọ́ N50bn COVID-19 tí CBN gbé jáde
- Father's Day fa gbas-gbos láàrin Mercy Aigbe àti ọkọ rẹ̀ tẹ́lẹ̀, Gentry, ọkọ́ ní òun le tú àwọn àṣírí ìwà nọ̀bì rẹ̀ síta
- Wo ìdí tí EFCC fi fẹ́ wádìí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun láti ọdun 2015 dí àsìkò yìí
- Wo ǹkan méje tí o lè má mọ̀ nípa Fola Alade to ya ilé '1004 Estate' tó dolóògbé
- Timothy Obadare ìránṣẹ́ Ọlọ́run to fọ́ lójú ìta ṣùgbọ́n tó ríran jù ọ́pọ́ wòlíì lọ
Ogagun agba Onyema Nwachukwu salaye pe, wọn ti da ọpọ omo ogun lọ si agbegbe naa lati wọnu igbo lọ.
Lọjọ Eti ni awọn ọmọ ogun kọkọ doola ẹmi olukọ meji ati akẹkọọ marun un leyin ti wọn kọlu awọn ajinigbe naa.
Ni ọsan ni awọn ajinigbe naa yabo ile ẹkọ FGC Birnin Yauri Secondary School, ti wọn si ji awọn akẹkọọ ati olukọ gbe
Mo ṣetán láti wọ inú igbó lọ wa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé- Gomina ìpínlẹ̀ Kebbi
Ijọba Kebbi n gbiyanju lati doola gbogbo awọn ti wọn ji gbe
Gomina Abubakar Atiku Bagudu sọ pe oun ṣetan lati ṣaaju awọn to n lọ wa awọn ti ajinigbe ji.

Oríṣun àwòrán, Bagudu Facebook
Gomina ipinlẹ Kebbi, Abubakar Atiku Bagudu sọ pe o tẹ oun lọrun lati saaju awọn to n lọ wa akẹkọọ ti wọn jigbe.
O ni ko ni oun lara lati wọ inu igbo ti wọn gbagbọ pe wọn ko awọn ọmọ naa pamọ si lọ.
Gomina Bagudu sọrọ yii nigba ti o n sepade pẹlu Gomina Kayode Fayemi ti ipinlẹ Ekiti ati Gomina Badaru Abubakar ti ipinle Jigawa.
- Mo kú tì, nítorí pé àsìkò mi kòì tó láti padà sí ọ̀run- Kunle Ologundudu
- ''Oyún oṣù méjì ní Kemisola Ogunniyi gbé dé ọgbà ẹ̀wọ̀n, a sì ṣe ìtọ́jú rẹ̀ dáradára''
- Wo ìdí tí EFCC fi fẹ́ wádìí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun láti ọdun 2015 dí àsìkò yìí
- Fola Alade, 'Architect' tó ya àwòrán ọ̀pọ̀ ilé àti ọ́fíísì tí Naijiria ní ti kú!
- Ajínigbe sún gbàgbé láwọn 15 nínú àwọn 156 tí wọ́n jí gbé ní Tegina bá sálọ
- Ṣé lóòtọ́ ni àwọn ọmọ ogun òfurufú Nàìjíríà ṣèèṣì pa máàlú 1,000 ní Nasarawa?
Gomina Kebbi ni oun ko ni lọ si ọffisi mọ bikoṣe lati tẹle awọn ọdẹ aṣọgbo lọ.
O ni mo seleri lati wọ inu igbo lọ pẹlu awọn ọdẹ lati lọ gba awọn akẹkọọ ti ajinigbe ji gbe ni Kebbi.
O ni ki awọn ọdẹ aṣogbọ bẹrẹ ipalẹmọ pe ni kete ti awọn osisẹ eleto aabo ba ti ni o ya ni oun naa setan.
Bayii, Ijoba ipinlẹ Kebbi ti ti awọn ile ẹkọ meje pa nitori iṣẹlẹ ijinigbe to waye ni Federal Government College, Birnin Yauri,.
Wọn fi eyi sita ninu atéjade wọn ti wón fi ṣalaye bi wọn se ri eeyan mẹrin gba ninu awọn ti wọn ji gbe nile ẹkọ Yawuri Secondary School nipinlẹ Kebbi.
Ileeṣẹ ologun ni' Awon ọmọ ogun Operation Endangered Forest ati awọn omọ ogun ofurufu Naijiria lo ri wọn ko.
Ogagun agba Onyema Nwanchukwu to buwọlu atẹjade naa ni ẹmi ọmọ ogun kan bọ si iṣẹlẹ naa.
- Ajínigbe sún gbàgbé láwọn 15 nínú àwọn 156 tí wọ́n jí gbé ní Tegina bá sálọ
- Fola Alade, 'Architect' tó ya àwòrán ọ̀pọ̀ ilé àti ọ́fíísì tí Naijiria ní ti kú!
- Ṣé lóòtọ́ ni àwọn ọmọ ogun òfurufú Nàìjíríà ṣèèṣì pa máàlú 1,000 ní Nasarawa?
- Ẹ wo bí olówó 'billionaire', Usifo Ataga ṣe kú ikú òjijì ní Eko
- Àjọ JAMB ṣèlérí ìdánwò mìí fún àwọn tí NIN jákulẹ̀, ó tún fòfin de ibùdó CBT 25















