Ondo rape case: Àwọn ara Ondo lu olè, Emmanuel Joseph tó ń jí ǹkan lọ́wọ́ arúgbó sí ẹsẹ̀ kan ayé, ẹsẹ̀ kan ọ̀run- ọ̀gá ọlọ́pàá Ikoro

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin to gba igboro kan ni Ondo bayii ni pe ẹni ọdun 35 tún fipá bá ìyá ẹni ọdun 80 lòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ondo
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo tí mú ọkùnrin kan, Emmanuel Joseph ẹni ọdún márùnlelọ́gbọn tí wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó fipá bá ìyá ọgọ́rin ọdún lòpọ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ondo
Wọ́n fẹ̀sùn kan Emmanuel pé ó gbà ojú fèrèsé ìyá wọlé lágbègbè Lotogbe ní ìjọba ìbílẹ̀ Ondo West tí ó sì mú àdá dání láti fi halẹ̀ mọ́ ìyá náà tí ó sì bá a sùn.
Ìròyìn sọ pé ó kó owó bákan náà ló kọ owó ìyá òun nigba ti iròyìn mìíràn sò pé ẹni a fẹ̀sùn kàn òun wọ inú ilé ìyá bí ẹni tó fẹ́ gba àgbo ni ẹ̀yìnkùlé ilé náà.
- Pipa ní wọ́n gbọ́dọ̀ pa àwọn agbébọn tí wọ́n ń jí àwọn ènìyàn gbé, ẹ da ọ̀rọ̀ Sheik Gumi nù -Aisha Yesufu
- Ẹranko àìmọ́ kan wọ Nàìjíríà, ó pa ènìyàn mẹ́rin ní Benue- ilé iṣẹ́ ọmọogun ni ìròyìn òfegè ni
- Kò sí ìpínlẹ̀ tí ijọba mi kò tíì fọwọ́ bà sí rere- Ààrẹ Muhammadu Buhari
- Alága ìjọba ìbílẹ̀ Eti-Osa, Eko tí jádé láyé lẹ́yìn tó ṣe àìsàn
- A ti fi páńpẹ́ ọba mú ènìyàn mẹ́ta lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Iwo Road, Ibadan - Ọlọ́pàá
- Wo ìdí tí EFCC fi fẹ́ wádìí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun láti ọdun 2015 dí àsìkò yìí
- Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
Ọ̀kan nínú àwọn tó jẹri sí bí ọ̀rọ̀ náà ṣe jẹ́ tó pé ara rẹ̀ ni Julianah Owolabi ṣàlàyé pé ariwo ìyá ni àwọn ènìyàn gbọ́ tí wọn fi já ilẹ̀kùn ìyá wọlé tí wọ́n sì bá ọkùnrin náà ni ìhòòhò.
Owolabi ni ẹni a fẹ̀sùn kan yìí kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa mú nǹkan ìjà derùba àwọn ènìyàn ládùúgbò tí yóò sì má jàwọ́n lólè.
Ìròyìn tún fi ìdí rẹ̀ mú lé pé àwọn ọmọ ẹni tí ọ̀rọ̀ kàn yìí tí gbé ìyá wọn kúrò ní agbègbè náà nítorí ìtìjú.
Ẹni a fẹ̀sùn kan náà bẹ̀ ìyá àgbà náà láti fi ori jí òun nítorí òun ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde ní ẹ̀wọ̀n ni. " Ẹ dárí jì mi, tí nkankan bá ti sọ pé kí n lọ jalè tàbí fi ipá bá ènìyàn lò pọ̀ máa ṣe ni, mo dá ara mi lẹ̀bi fún èyí tí mo se yìí.
"Mi o mọ nǹkan tó bá lè mi, wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ fi mí sílé l'Ẹ́wọ̀n ni kí àwọn òṣìṣẹ́ ẹ̀ka idajọ tó lọ fún ìyanṣẹ̀lódì nítorí ìwà burúkú tí mò ń hù yìí. Ó ti pẹ́ tí mo ti ń ṣeé, ẹ jọ̀wọ́ ẹ dáríjìmí.
- Wo ìdí tí EFCC fi fẹ́ wádìí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun láti ọdun 2015 dí àsìkò yìí
- Father's Day fa gbas-gbos láàrin Mercy Aigbe àti ọkọ rẹ̀ tẹ́lẹ̀, Gentry, ọkọ́ ní òun le tú àwọn àṣírí ìwà nọ̀bì rẹ̀ síta
- Àlàyé rè é lórí bí o ṣe lè gbá owó ìrànwọ́ N50bn COVID-19 tí CBN gbé jáde
- Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
- Ìgbẹ́jọ́ Kemisola Ogunniyi kò wáyé lóní, ó tún dọ̀la, ṣùgbọ́n... - Agbẹjọ́rọ̀
- 'Kò sí ẹni tó lè ní kí a má wá sí Èkó, iwọ́de òní pẹ̀lẹ́ kùtù la fẹ́ ṣe'
- Lẹ́yìn ìjà tò gbẹ̀mí èèyàn bíi mẹ́ta, Makinde sè ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ àlákòóso Amọtẹkun
Kini Ileeṣẹ ọlọpaa fidiẹ mulẹ fun BBC lori iṣẹlẹ yii?
Agbenusọ ọlọ́pàá ni ìpínlẹ̀ Ondo Tee-Leo Ikoro ṣalaye fun BBC pe irọ pata ni pe Ole naa, Emmanuel ba iya agbalagba naa sun.
Ikoro ni pe nitootọ ni ole naa maa n ja awọn agbalagba lole to si maa n dẹru ba wọn lati gab nkan lọwọ wọn.
O ni pe nitootọ ni ọwọ awọn eeyan tẹ Ole naa tó si di pe wọn lu Emmanuel naa de bi pe o wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
O ni oun ko nii lọkan lati fipa ba iya arugbo naa sun bikose pe ki oun ja iya naa lole
Ọga ỌLọpaa ni pe ikọlu ni ẹsun naa kii ṣe ifipa ba arugbo lo pọ.
- Wo ìdí tí EFCC fi fẹ́ wádìí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun láti ọdun 2015 dí àsìkò yìí
- Father's Day fa gbas-gbos láàrin Mercy Aigbe àti ọkọ rẹ̀ tẹ́lẹ̀, Gentry, ọkọ́ ní òun le tú àwọn àṣírí ìwà nọ̀bì rẹ̀ síta
- Àlàyé rè é lórí bí o ṣe lè gbá owó ìrànwọ́ N50bn COVID-19 tí CBN gbé jáde
- Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
- 'Kò sí ẹni tó lè ní kí a má wá sí Èkó, iwọ́de òní pẹ̀lẹ́ kùtù la fẹ́ ṣe'
- Lẹ́yìn ìjà tò gbẹ̀mí èèyàn bíi mẹ́ta, Makinde sè ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ àlákòóso Amọtẹkun

Oríṣun àwòrán, others
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ẹni ọdún 40 tó fipá bá ìyá ọdún 60 lòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun
Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ogun tí tẹ afunrasí kan ẹni ogójì ọdún Adesina Adebowale tó fipá bá ìyá ẹni ọgọ́ta ọdún lòpọ̀.
Agbenusọ ọlọ́pàá Ogun DSP Abimbola Oyeyemi sọ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ́jọ́ ajé ṣàlàyé pé àwọn lépa ọkùnrin náà lẹ́yìn tí ọmọ ẹni tí ọ̀rọ̀ náà ṣẹlẹ̀ sí mú ẹjọ́ wá sí àgọ́ ọlọ́pàá Idanyin.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ, ó ní ọmọ ẹni tí iṣẹ̀lẹ̀ náà bá sọ pé ní nǹkan bí aago mẹ́rin ìrọ̀lẹ́ ni afunrasí náà já ìlẹ̀kùn wọ ilé ìyá òun tó sì fi ipá bá lòpọ̀.
- Dino Melaye fi ọkọ Rolls Royce bùgá lórí Instagram, ni oníṣòwò ọkọ́ bá ní kó wá san gbèsè owó ọkọ̀ tó jẹ́ òun
- Ẹ wo ohun tí a mọ̀ nípa bí agbébọn ṣe gbẹ̀mí sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀, Titus Badejo Ejanla ní ìlú Ibadan
- Ọwọ́ tẹ ọmọdébìnrín tó jí ara rẹ̀ gbẹ́ nítorí ìyá rẹ̀ ní kó lọ kọ́ ẹ̀kọ́ láti ṣe dókítà
- Ẹ wo bí olówó 'billionaire', Usifo Ataga ṣe kú ikú òjijì ní Eko
- Ṣé lóòtọ́ ni àwọn ọmọ ogun òfurufú Nàìjíríà ṣèèṣì pa máàlú 1,000 ní Nasarawa?
- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ ọdún 40 tó fipá bá ìyá ọdún 60 lòpọ̀ ní
Lẹ́yìn èyí ni ọlọ́pàá dá àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ síta láti mú ọ̀daràn náà. "wọ́n lépa rẹ̀ wọn sì rí mú, bákan náà ni wọ́n ti tètè gbé ẹni tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀ sí lọ sí ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú.
Agbenusọ ọlọ́pàá Ogun DSP Abimbola Oyeyemi " Ọ̀daràn náà jẹ́wọ́ pé lóòótọ́ ni òun hu ìwàbàjẹ́ bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Oyeyemi ṣe sọ.
O tún ṣàlàyé pé Kọmísọ́nà ọlọ́pàá Edward Awolowo Ajogún tí ni kí wọ́n gbé ọ̀daràn náà lọ sí ẹ̀ka CIID fún ìwádìí àti ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìgbẹ́jọ́
- Wo ǹkan méje tí o lè má mọ̀ nípa Fola Alade to ya ilé '1004 Estate' tó dolóògbé
- Father's Day fa gbas-gbos láàrin Mercy Aigbe àti ọkọ rẹ̀ tẹ́lẹ̀, Gentry, ọkọ́ ní òun le tú àwọn àṣírí ìwà nọ̀bì rẹ̀ síta
- Àlàyé rè é lórí bí o ṣe lè gbá owó ìrànwọ́ N50bn COVID-19 tí CBN gbé jáde
- Ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ti dóòlà ẹ̀mí díẹ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Kebbi
- Ìgbẹ́jọ́ Kemisola Ogunniyi kò wáyé lóní, ó tún dọ̀la, ṣùgbọ́n... - Agbẹjọ́rọ̀
- 'Kò sí ẹni tó lè ní kí a má wá sí Èkó, iwọ́de òní pẹ̀lẹ́ kùtù la fẹ́ ṣe'















