Unilag shut down?: Àwọn aláṣẹ Fásitì UNILAG ti ibùgbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pa torí ọwọ́jà Covid-19

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn alaṣẹ ileewe naa gbe igbesẹ naa lati da abo bo awọn akẹkọọ naa lọwọ ajakalẹ aarun Coronavirus ti ọwọja kẹta ni ipinlẹ Eko.
Awọn alaṣẹ ileẹkọ Fasiti ipinlẹ Eko (UNILAG) ti paṣẹ ki gbogbo awọn akẹkọọ kuro ni ọgba ileẹkọ naa.
Awọn adari ileẹkọ naa ni ki awọn akẹkọọ naa kuro ni yara igbe ileẹkọ naa.
Ṣé ǹkan oṣù rẹ ń dà hìì hìì lẹ́yìn tóó gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19? Ẹ gbọ́ tuntun lẹ́nu àwọn Dókítà
Bakan naa ni wọn kede pe awọn akẹkọọ yoo bẹrẹ ẹkọ kikọ lori ẹrọ ayelujara lati Ọjọ Kẹrindinlọgbọn, Oṣu Keje, ọdun 2021.
Awọn alaṣẹ ileewe naa gbe igbesẹ naa lati da abo bo awọn akẹkọọ naa lọwọ ajakalẹ aarun Coronavirus ti ọwọja kẹta ni ipinlẹ Eko.
Bakan naa ni wọn fi lede pe ọpọlọpọ akẹkọọ lọ ti wa ni ileewosan lori aisan to ṣeeṣe ko niiṣe pẹlu aarun Coronavirus.
- Sunday Igboho, Akintoye àtàwọn míràn fa Buhari, Malami àtàwọn míì lọ síwájú ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC
- Oríire ńlá ló jẹ́ fún àwọn ọmọ Naijiria pé orílẹ̀-èdè yìí ṣì wà ní ọ̀kan ṣoṣo- Buhari
- Mo gbọ́ pé babaláwo mẹ́ta ló tẹ̀lé àwọn DSS lọ sí ilé Sunday Igboho- Gani Adams
- Aya Aarẹ Ghana ati aya ìgbákejì Aarẹ Ghana ti dá gbogbo owó oṣù tí wọ́n gbà láti 2017 padà sápò ìjọba
- Gbẹgẹdẹ gbiná, ṣọ́jà àtàwọn jàǹdùkú fìjà pẹẹ́ta lọ́jà Ladipo l'Eko
- Mọ si nípa àbá òfin tí yóò mú kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti le gbẹ́sẹ̀ lé ilé tàbí ilé ìtura tí ífipá bálòpọ̀ bá ti wáyé















