Is Tinubu leaving APC?: Irọ́ ni pé Bola Tinubu fẹ́ kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú APC- Agbẹnusọ Aṣíwájú

Oríṣun àwòrán, @BAT
Leyin ipade ti awọn eekan ẹgbẹ All Progressives Party pe nilẹ Yoruba ni iroyin kan jade pe o ṣeeṣe ki Oloye Bola Tinubu paarọ ẹgbẹ oṣelu rẹ.
Alagba Bisi Akande to dari ipade yii ni ilu Eko si ti ni ẹnu awọn ko lori pe ki ẹkun Iwọ oorun Guusu ilẹ Naijiria fa oludije ipo aarẹ silẹ.
Ko sọ pato ẹni ti oludije yi yoo jẹ ṣugbọn wọn ni awọn yoo ṣi maa ṣe ipade loore koore.Fayemi ní òun ṣetán láti gbéná wojú àwọn alágbára tí kò jẹ́ kí Nàìjíríà tẹ̀síwájú
Bakan naa lo ni ki awọn oludije yooku pada wa to lẹyin ẹnikẹni to ba jawe olubori nidi idibo abẹle APC.Bí Jibrin ṣe kúrò ní ẹgbẹ̀ òṣèlú APC kò níi ṣe pẹ̀lú Bola Tinubu- Agbẹnusọ ìpolongo
Lori ọrọ ki awọn oludije maa ta abuku ara wọn, ipade naa sọ pe eyi ko bojumu ni paapa pe ọmọluabi lo yẹ ki awọn oludije ati alatilẹyin wọn jẹ.Ògo Naijiria yóò padà wá tí mo bá di Ààrẹ - Pasitọ Tunde Bakare
- Ẹbí kan pàdánù ọmọ mẹsan-án nínú èèyàn 435 tí omiyalé pa
- Ẹkún tún sọ ní Zamfara, àwọn agbébọn pa èèyàn 48
- Ẹ gba ìpínlẹ̀ Eko kúrò lọ́wọ́ àwọn àjòjì - Atiku sí Bode George
- Ẹni tí mo máa gbé ìjọba lé lọ́wọ́ rèé - Ààrẹ Buhari
- Èsì ìdánwò UTME abala àkọ́kọ́ yóò jáde lọ́sẹ̀ yìí- Àjọ JAMB
- Kí nìdí táwọn iléeṣẹ́ bàlúù ní Nàìjíríà ṣe fẹ́ wọ́gilé ìrìnnà òfúrufú ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé?
- Wo ọ̀nà tí wọ́n ń pè ní "ọ̀nà ikú" tí àwọn ènìyàn ṣì ń ṣe ìrìnàjò lórí rẹ̀ síbẹ̀
- Mo dúpẹ́ ó! Mo bẹ́ orí fún gbogbo àgbẹ̀ àti olùfọkànsìn tó ń dáwó fọ́ọ̀mù Ààrẹ fún mi àmọ́ ẹ jẹ́ n lo óògùn ara mi - Emefiele
Se lootọ ni Bola Tinubu n fi ẹgbẹ APC sile?
Opo lo n sọrọ lori ayelujara pe lẹyin ti apero ti wọin ṣe ni ilu Eko ti faaye gba ẹnikẹni lati dije ni Tinubu ti n tun ero rẹ pa.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 1
Sugbon ọkan lara awọn alatileyin Senatọ naa to n dije dupo labẹ asia ẹgbẹ APC ti sọrọsoke pe irọ to jina si ootọ ni.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 2
Asiwaju sọ pe ẹru kò ba odo Bola Tinubu rara ninu ẹgbẹ APC
Bakan naa ni Honorebu Ayo Oyalowo, ọkan pataki ninu eekan ẹgbẹ APC to tun jẹ oludije ni Ogbomoso ti ni ọrọ ko ri bẹẹ.
Oyalowo sọ eyi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ iroyin amohunmaworan Arise.
O ni pe Asiwaju lo ni iye nọmba akopa dẹligéèti to pọ julọ titi di oni yii.
Ati pe awọn akopa naa si ti fi Baba Bordellion lọkan balẹ pe didun ni ọsan yoo so fun un ti asiko idibo lati ayn oludije ba ti ya ni Abuja.
- Bíbéli mi ló sọ pé kí n fẹ́ ìyàwó omidan mẹ́rin, kìí ṣe ẹ̀ṣẹ̀- Pásítọ̀
- A kọ̀ láti yí ọkàn wà padà lórí ìpinnu Yorùbá Nation- Ilana Omo Oodua
- Afurasí Oníṣòwò ǹkan ìjà olóró méje kó sí pańpẹ́ Ọlọ́pàá ní Jos àti Taraba
- Mi o rí òṣèrékùnrin tí kìí yan àlè lẹ́yìn ìyàwó wọn- Iyabo Ojo
- Wòlíì Olubọla ni wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ọkọ̀ ọmọ ijọ̀ lọ ní Abeokuta
- Mo bẹ̀rẹ̀ sí ń wọ ìjáàbù nítorí àwọn okùnrin máa ń wo bẹ̀bẹ̀rẹ́ ìdí mi tí mo bá ń wàásù - Sister Kate
- Wo ohun mánigbàgbé mẹ́fà nípa Gbenga Adeboye lẹ́yìn ọdún 19 tó kú













