Nigeria 2023 election: Aminu Waziri Tambuwal fi èròńgbà rẹ̀ láti díje dupò aàrẹ̀ Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, @Sokoto Gov office facebook
Kini o ṣokunfa ipinnu Aminu Waziri Tambuwal tó fẹ̀ gbé àpótí ìdìbò ààrẹ Nàìjíríà nígbà kejì?
''Mo ti tẹti gbọ ohun tawọn ọmọ ẹgbẹ wa sọ,tori naa lo mu mi kede erongba mii lati dije dupo aarẹ Naijiria.''
Ọrọ yi ni Gomina ipinlẹ Sokoto Amnu Waziri Tambuwal fi se ikede erongba rẹ lọjọ Aje toun naa si darapọ mọ awọn ton gbero lati di ipo aarẹ Naijiria muninu idibo 2023.
- Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu
- Wo àwọn ọmọ Yorùbá mẹ́fà tí ẹnu ń kùn lórí ìbò ààrẹ ọdún 2023
- Ọmọ Nàíjíríà, ẹ yé yan àwọn ‘Grandpa’ ní ààrẹ, ẹ wá ọlọ́gbọ́n ọ̀dọ́ tó tún sán-an-gun - Seyi Makinde
- Ẹ̀yín àgbà Yorùbá, ẹ dìde yanjú aáwọ̀ òṣèlú láàrin Tinubu àti Osinbajo, bíbẹ̀ẹ́kọ́... - Ajulo
- Sanwo-Olu kède iye tí àwọn aráàlú yóò máa wọ ọkọ̀ ojú irin ayára bí àṣá tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ́ rà
- Pásítọ̀ ti ríran sí mi pé mà á jẹ Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti ọdún 2018- Dele Momodu
- Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé
Gomina yi to ti fi igba kan jẹ olori ile asofin Naijiria fi ero rẹ lelẹ ni ipinlẹ Sokoto lẹyin ipade to se pẹlu awọn alẹnulọrọ.
Tambuwal sọ pe oun gbe igbesẹ yi lẹyin tawọn to wa ni ẹka ẹgbẹ naa nipinlẹ Sokoto kesi oun ati pe oun ti setan lati bẹrẹ ijiroro kaakiri Naijria lati le tẹsiwaju pẹlu erongba yi.
''Mo ti gbọ ohun awọn agbaagba ẹgbẹ obinrin,ati ọdọ lori pe ki n bẹrẹ ki n si tẹsiwaju pẹlu ijiroro nipa erongba mi lati dije ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ wa''
Ipo wo ni Tambuwal ni oun kọkọ fẹ du?
Aminu Tambuwal tẹsiwaju pe: ''nigba tawọn ọmọ ile asofin Naijiria ti saa keje kan si mi pe awọn fẹ ki n di ipo olori ile mu nigba na,
Mo sọ awọn asọkalẹ kọọkan to fi mọ pe mo ni awọn baba nigbẹjọ bi Sheu Shagari ati Aliyu Wamakko ati awọn meji mii ni ipinlẹ Sokoto''
Koda, Mo sọ fun wọn pe ki wọn lọ si ipinlẹ mi ki wọn si ba awọn olori yi jiroro, bi wọn ba fasẹ sii, mo ma a gba aba yin ti ma a si du ipo olori ile asofin''
- Àjọ ìṣọ̀kan ilẹ̀ Àdúláwọ̀ fòfin de Burkina Faso lórí ìdìtẹ̀gbàjọba
- Tí òògùn owó bá wà nínú Ifa ni, n kò bá ti kọ́ ilé ńlá fún ara mi- Babaláwo
- U.S. yóò máa fún àwọn ọmo Nàìjíríà kan ní físà ìwé ìrìnnà láì ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
- Kìnìún méjì ṣekùpa olùṣọ́gbà ẹranko, wọ́n sì sálọ
- Ẹ foríjìnmí, ẹlẹ́ran ara ni mí- Gbajúgbajà adẹ́rìnpòṣónú, Bae_U
- Ọkọ mi tẹ́lẹ̀ àti Adekaz kò fi ìgbà kankan jẹ́ ọ̀rẹ́, kìí sẹ ọ̀rẹ́ ọkọ mi ni mo fẹ́ - Mercy Aigbe
O fi kun pe: ''Sheu Shagari sọ fun wọn nigba naa pe 'bi ẹ ba fẹ fa ọmọ wa kalẹ, ko gbọdọ jẹ nitori ẹlẹyamẹya tab notori ẹsin' ''
Tambuwal pari ọrọ rẹ pe erongba tootọ lawọn eeyan gbọdọ lo lati mu olori Naijiria ti yoo se orileede naa ati gbogbo araalu lanfaani.
Ta ni Tambuwal lagbo oselu Naijiria?
Odu ni Aminu Waziri Tambuwal lagbo oselu.
Agbẹjọro yi yan oselu laayo to si jẹ ọkan lara awọn eekanninu ẹgbẹ oselu PDP to wa bayii.
Saaju ki o to darapọ mọ ẹgbẹ PDP abẹ asa ẹgbẹ All Nigeria Congress Party ANCP lo dje dupo to fi kọkọ lọ si ile asofin agba Naijiria lọdun 2003.
Lati igba taa n wi yi, ile asofin Naijiria lo ti di ilumọọka paapa bo ti se di olori ile asojusofin lọdun 2011-2015.
Ninu irinajo Tambuwal, kini kan to jẹ́ yọ ni bo ti se n fo lati inu ẹgbẹ oselu kan si omiran.
O kere tan lati igba to ti darapọ mọ ẹgbẹ oselu ANPP to fi bẹrẹ lọdun 2003, o ti paarọ ẹgbẹ lati ANPP lọ si DPP,ANPP,PDP to si tun bẹ lọ si APC ko to tun pada si PDP bayii:
•2003 ANPP
•2007 DPP
•2007 ANPP
•2007 PDP
•2014 APC
•2018 PDP
Tambuwal ati erongba rẹ lati di aarẹ Naijiria kii se nkan to sẹsẹ bẹrẹ loni
Lọdun 2018 oun ati awọn oludije mii jijọ dije du tikẹẹti ẹgbẹ oselu PDP lati soju ẹgbẹ naa.
Ko pegede ninu igbiyanju yi sugbọn o tun ti wa gbe apoti idibo bayii lati ri tikẹẹti ẹgbẹ PDP gba lati soju wọn ninu idibo 2023.
Tambuwal ti wa kun awọn oludije mii to jade pe awọn fẹ du ipo aarẹ lọdun 2023.
Ninu ẹgbẹ PDP yoo maa koju awọn oloselu mii to dantọ bi Abubakar Bukola Saraki, Atiku Abubakar ati awọn miran.
- "Á lọ yíká gbogbo ilẹ̀ Yorùbá láti bèèrè fún ìdáǹdè Sunday Igboho"
- Fathia Balogun kéde aṣọ ẹbí ₦150,000 àti ₦120,000 fún ọjọ́ ìbí rẹ̀
- Sanwo-Olu kède iye tí àwọn aráàlú yóò máa wọ ọkọ̀ ojú irin ayára bí àṣá tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ́ rà
- Ẹ̀yín àgbà Yorùbá, ẹ dìde yanjú aáwọ̀ òṣèlú láàrin Tinubu àti Osinbajo, bíbẹ̀ẹ́kọ́... - Ajulo
- Òǹkọ̀wé kan dèrò àtìmọ́lé torí ó bú Ààrẹ lórí ayélujára
- Ilé aṣòfin n rẹkẹ, Boris Johnson takú, tá ní yóò bóri lórí awuyewuye ''party'' ọjọ́ ìbí?
- Osun la fẹ́ kí ìgbẹ́jọ́ ikú Timothy Adegoke ti wáyé, kìí ṣe Abuja - Mọ̀lẹ́bí yarí


















