Tí mo bá rí obìnrin tó kò níṣẹ́ lápá, mó máa ń ní kí wọ́n wò mí ṣe àríkọ́gbọ́n
Jane Ifeoma ni orukọ rẹ n jẹ, obinrin bi ọkunrin tabi ka tilẹ ni obinrin to ju ọkunrin lọ ni.
Iṣẹ ọwọ rẹ to yan laayo ko doju ti i rara. Ko da o ni ohun ti oun n lo lati fi fun eeyan mẹẹdogun lounjẹ ninu ile oun niyii.
Iṣẹ birikila lo wayan laayo to si maa n yaa lor lati wa iṣẹ lọ ibikibi ti wọn ba ti n kọle.
- 'Ẹ jọ̀ọ́, a ò fẹ́ gbọ́ òfófó ìròyìn mọ́ pé àbúrò mi gún bàbá àti ìyá mi pa' ó ti tó gẹ́!
- Àdó olóró tí wọ́n fi ń pa iná àdó olóró míì ló gbiná l'Ekiti - Ọlọ́pàá Ekiti
- Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode
- Ohun tó ti yá kan kìí pẹ́ mọ́, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ fún Àmọ̀tẹ́kùn dé!
- Ìsọkúsọ ni Olúbàdàn ń sọ, àwa la lè yọ́ lóyè. òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun
"Ti wọ́n ba sọ fun mi pe kii ṣe iṣẹ obinrin, mo maa n sọ fun wọn pe ko ni ohunkohun ṣe pẹlu pe mo jẹ obinrin".
Ọp ajalu lo ṣẹlẹ si i. "Ọmọ méje ni mo bí ṣùgbọ́n gbogbo wọ́n ti ṣaláìsí".
O mọkan o si gba ọkọ rẹ nimọran fun itẹsiwaju idile wọn.
Ninu owo to n ri lo ti bẹrẹ ile ara rẹ diẹ diẹ titi ti oun fi di onile ara rẹ.
- Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire
- Ìjọba Eko sọ pé ká má tọrọ bárà mọ́, wọ́n tún fòfin de kẹ̀ẹ̀kẹ́ tá a fi n ṣiṣẹ́ - Àwọn àkàndá ẹ̀dá
- Mí ò bẹ̀bẹ̀ fún oyè igbákejì alága APC kí wọ́n tó ó fún mi - Abiola Ajimobi
- Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn









