Nigeria Democracy: Buhari buwọ́lu àbádòfin 'June 12' gẹ́gẹ́ bí àyájọ́ ọjọ́ ìjọba àwarawa

Oríṣun àwòrán, Twittter/Muhammadu Buhari
Lẹyin ọ rẹyin, ''June 12'' pada ayajọ ọjọ isinmi ijọba awarawa lorilẹede Naijiria lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari buwọ lu abadofin naa.
Oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lo fọrọ naa lede.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 1
Ohun ti igbesẹ yii tumọ si ni pe lati akoko yii lọ, ko ni si isinmi lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un mọ to jẹ ayajọ ọjọ ijọba awarawa tẹlẹ.
Ọjọ kọkandinlọgbọn yoo kan jẹ ọjọ ifilọlẹ ati iburawọle ijọba tuntun lorilẹede Naijiria.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 2
Igbesẹ aarẹ lati buwọlu ''June 12'' waye ni ọjọ meji peri si ọjọ kejila oṣu kẹfa tii ṣe Ọjọru.
Laipẹ yii ni ile igbimọ aṣofin agba mejeeji l'Abuja fi abadofin naa ranṣẹ si Aarẹ Buhari.














