Siasia: Ọlọ́pàá Bayelsa ṣalàye ibi tí wọ́n bá ìyá Siasia tó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé

Oríṣun àwòrán, Other
Iroyin to tẹwa lọwọ latọdọ ile iṣẹ Ọlọpaa Bayelsa ni peawọn agbebọn ya wọ ile arabinrin Beauty Siasia wọn si ji i gbe lọ.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa, SP ASinim Butswat fi ranṣẹ si ile iṣẹ BBC o fi aridaju han pe lootọ ni wọn ji iya agbabọọlu ati akọnimọọgba Naijiria tẹlẹ ri, Samson Siasia gbe.
- Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko
- Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti
- Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu
- Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare
- Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò
Atẹjade naa ṣalaye pe ni nkan bi agogo meji oru ganjọ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu keje ọdun 2019 ni awọn agbegbọn ti ẹnikẹni ko mọ gba ọna oju omi River Nun wọ ile Arabinrin Beauty.
Ẹni ọdun ọgọrin ọdun ni Arabinrin Beauty to n gbe ni ilu Odoni ni ijọba ibilẹ Sagbama ipinlẹ Bayelsa ti wọn si ji i gbe lọ gba ori omi lọ si ibi ti ẹnikẹni kò mọ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Laduntan Oyekanmi di ìyálóde tuntun fún ilẹ̀ Ibadan
- Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
- Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà
- Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú...
- MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò
- Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè
- Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria
- Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin
- Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́...’ rèé
Kọmiṣana ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa ni atoun ati ikọ amuṣẹya awọn ti ṣe ibẹwo si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye ati pe ile iṣẹ awọn pẹlu ajọṣep awọn mii tọrọ kan nipa aabo ti kan lu agbami wiwa awọn agbenipa yii ati lati doola iya ti wọn ji gbe.









