Sunday Igboho: Ìkọlù tí ẹ̀ṣọ́ aláàbò ṣe sí Sunday Igboho, Inú wa kò dún sí ìjọba''

Oríṣun àwòrán, Others
Ọba Ẹlẹrinmọ ti Ẹrinmọ Ijẹsha ni ilu Ekiti, Oba (Dr) Michael Ajayi, Arowatawaya II ti ni inu awọn lọbalọba ko dun si iṣẹlẹ ikọlu si Sunday Igboho to waye laipẹ yii.
Oba (Dr) Michael Ajayi, Arowatawaya II lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ ni nkan to ba ṣẹlẹ si ọmọ Yoruba ẹyọkan, gbogbo wọn ni o ṣẹlẹ si.
O ni awọn lọbalọba ko dakẹ rara, nitori labẹlẹ ni wọn gbe igbeṣẹ lati rii pe opin de ba gbogbo wahala yii.
- Gbogbo ìgbèsẹ̀ tí Sunday Igboho ń gbé ni mo mọ̀ sí gẹ́gẹ́ bí Aare Ona Kakanfo - Gani Adams
- Ìdí rèé tí àwa lọ́balọ́ba fi dákẹ́ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù Sunday Igboho - Oluwo tí Iwo
- Ẹ wo obìnrin tó pàdé ọkọ́ lẹ́ni ọdún 47 , tó sì bímọ lẹ́ni àádọ́tá ọdún
- Gbajúmọ̀ òṣèré Bollywood ní India, Dilip Kumar, jáde láyé
- Hàà! Yomi wàá ṣẹ̀wọ̀n o! Oò ṣe bí ọlọ́pọlọ rárá, ò kàn ń fi àṣírí Baba Ijesha àti Iyabo Ojo gòkè ni - Femi Branch
- Àwọn alátìlẹyìn Sunday Igboho ṣe ìwọ́de ní Ibadan, wọ́n tọrọ nkan márùn-ún lọ́wọ́ Olubadan
- Àwòrán bí ó ṣe ńlọ rèé níbi ìsìnkú TB Joshua lónìí
''Mi o ro pe a dakẹ rara, ọmọ ẹni kii buru ka fi fun ẹkun pa jẹ''.
''Nkan to ba ti ba ẹnikan, o ba gbogbo wa naani, inu wa ko dun si''.
Bakan naa ni Ọba Ẹlẹrinmọ ti Ẹrinmọ Ijẹsha ni nkan ti awọn ẹṣọ alaabo pẹlu atilẹyin ijọba apapọ ṣe si Sunday Igboho ko bojumu rara.
- Ìdí rèé tí àwa lọ́balọ́ba fi dákẹ́ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù Sunday Igboho - Oluwo tí Iwo
- Àwọn olólùfẹ́ Baba Ìjèsà gbé ìgbà Gofund Me láti ràn án lọ́wọ́ sàn owó tí yóò fí ṣé ẹjọ́
- Sàdáńkátà! Ẹ̀yin ẹ̀létò ààbò, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ yín fún ìkọlù sí ilé Sunday Igboho - Ààrẹ Buhari
- Àwọn agbébọn pa ààrẹ orílẹ̀-èdè Haiti nílé rẹ̀ lóru mọ́jú
- Láéláé! A ò faramọ́ àbá àwọn Gómìnà Gúúsù pé ààrẹ Nàìjíríà gbọdọ̀ wá láti ẹkùn wọn lọ́dún 2023 - Ẹgbẹ́ Arewa
- Bimpe Oyebade tú àṣírí bí Yomi ṣe ń gbógun tìí torí ìbalòpọ̀
- Ìgbeyàwó òṣèrébìnrin mìràn tún forí ṣánpọ́n
- Ìkọlù DSS sílé Sunday Igboho tàpá sófin, ìwà ìjọba ológun ni - Falana
Oba Micheal ni awọn ko fi igba kan gbọ pe wọn fi iwe ipe ranṣẹ si Sunday Igboho, wọn kan dede ṣekọlu si ni oru mọju ni.
O ni awọn ni igbagbọ wi pe awọn aṣoju wọn ni ile aṣofin lorilẹede Naijiria naa n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe iya ko jẹ ọmọ ilẹ Yoruba kankan ni ọna aitọ.
















