Amòfin: Àwọn ẹrù kan wà tí kò yẹ nínú àpamọ́wọ́

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Takọ tabo ló ń gbé Àpamọ́wọ́ lágbàáyé báyìí.
Gbogbo ìran, èdè àti ẹ̀yà ló ń fi Àpamọ́wọ́ kó ǹkan tó se pàtàkì sí wọn.
Bí ọ̀làjú sé ń dé ni Àpamọ́wọ́ àwọn ènìyàn se ń tóbi síi.

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kínní kò yẹ kó wà nínú Àpamọ́wọ́ rẹ?
Sùgbọ́n àwọn ẹrù kan wà tí kò bá òfin mu, tí à ń kó sínú àpamọ́wọ́ wa èyítí Ọlọ́pàá lè mú wa fún.
Ń jẹ́ kín lo kó sínú àpamọ́wọ́ rẹ?
Doyinsọ́lá Òdúkòmaiyà sọ àwọn ohun tó wà nínú àpamọ́wọ́ rẹ̀:
Asòfin James Ajibola sọ̀rọ̀ lórí àwọn ǹkan tí kò yẹ kó wà nínú àpamọ́wọ́ ẹni:
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Àwọn ọ̀nà tí á ń gbà gbé Àpamọ́wọ́ wa:
- Pìpọ̀n sẹ́yìn
- Fífà lọ́wọ́
- Fífi kọ́ èjìká
- Pípọ̀n sáyà
- Fífi kọ́ ọrùn














