Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri Nàìjíríà
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1

O ṣe ilẹ̀ ń jẹẹyan

Agba oṣere tiata, Abdulsalam Ishola ti ọpọ mọ si Charles Olumo Agbako ti jade laye

Owurọ Ọjọbọ ni Agbako dagbere faye lẹni ọdun mọkanlelọgọrun-un

Ẹkunrẹrẹ iroyin, pẹlu bi isinku rẹ yoo ṣe lọ wa ni bbc.com/yoruba

Ǹjẹ́ o ti gbọ́?

Pe kini?

Pe o le jokoo ni kọrọ yara rẹ ki ajọ to n ri iwọle-wọdeni Naijiria si mu iwe irinna rẹ wa ba ọ

Ni Naijiria yii naa abi nilẹ okeere?

Naijiria yii naa ni o, Immigration ti kede ilana mẹjo ti ẹni to ba fa gba iwe irinna yoo gbe lai ni de ọfiisi wọn

O o si jami si

Kan si oju opo bbc.com/yoruba fawọn igbesẹ naa

Ṣo o ranti Ganiyat Popoola, dokita tawọn agbẹbọn jigbe lati oṣu Kejila ọdun to kọja

Ṣeyi tawọn ẹgbẹ dokita tori rẹ yanṣẹlodi fọsẹ kan ninu oṣu kẹjọ

Ehn o, o ti gba itusilẹ lẹyin to lo oṣu mẹwaa ni ahamọ awọn ajinigbe naa

Ṣe wọn san owo itusilẹ ni?

Kan si oju opo bbc news Yoruba ti o ba fẹ mọ ẹkunrẹrẹ

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́