Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
Mama Oriki sọ ọna abayọ ti ko ni jẹ ki ede, aṣa ati iṣẹṣe Yoruba ko parun
BBC Yoruba kan si Ayo Ewebiyi Mama Oriki lati kọ ẹkọ lara bi akewi naa ṣe bẹrẹ aye rẹ ki o le jẹ koriya fun awọn ọdọ asiko yii.

Mama Oriki sọ bi agbega ede ati aṣa Yoruba ṣe jẹ oun logun pupọ lati kekere aye rẹ.
- Báwo ni mo ṣe lè sọ̀rọ̀ ìtùnú fún ẹni tí ọ̀kan rẹ̀ dàrú?
- Ìran Yorùbá ló ń fìyà jẹ mẹ̀kúnnù Yorùbá, kò sọ́nà níbi pé kí a pín nítorí...Femi Falana
- Ẹ̀yin Òbí, ẹ fi ọmọbìnrin yin sílẹ̀ láti ṣe iṣẹ́ tó wù wọ́n- Deborah tó ń fi ìlú bàtá àti gángan dárà
- ''N kò lè ṣe gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin, ṣùgbọ́n n kò mọ̀ títí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó''
- Wo akọrin Highlife kan tó ń kọrin bíi Lagbaja

Ayo Ewebiyi sọ bo ti ṣe gbe ede ati aṣa Yoruba kaakiri agbaye.
O mẹnuba bi awọn oyinbo ṣe n fẹ wa kọ ede ati aṣa iran Yoruba to dun lede to tun dara laṣa.
- Ìdájọ́ tí mo fẹ́ ni kí Monsura àti ọlọ́pàá tó pàá jọ lọ padè ní ọrùn láìpẹ́- Adepeju ìyá ọmọ tí ọlọ́pàá pa ní Eko
- Iṣẹ́ àgbẹ̀ ayé àtijọ́ níra púpọ̀ ní mo ṣe ń ṣe àgbẹ̀ inú àpò
- Ọkùnrin mẹ́wàá ló ti fipá bá mi lòpọ̀ rí, àbúrò ìyá mi lálákọ́kọ́- Oluwatobi Raji
- Wo bí Pásítọ̀ Adeboye, Wòlíì Iginla ṣe ń dárò ikú akẹgbẹ́ wọn David Yonggi Cho
- Ayẹyẹ ọdun Igogo gbérasọ ni ipinlẹ Ondo, ẹ wo bí ti ọdún yìí ṣe lọ

Iró ni pé ẹni tó bá ń kéwì tàbí ṣe ǹkan ìbílẹ̀ kìí sin Olodumare- Ayo Ewebiyi Mama Oriki
Mama Oriki mẹnuba ipa pataki ti awọn agba akewi bii Olanrewaju Adeoju, Ajobiewe ati awọn mii ti ko ki igbega le ba ede Yoruba.
Bakan naa lo sọ pataki ayelujara ti o fi n safihan iṣe ati ede Yoruba kaakiri agbaye.
- Okòòwò márùn ún tí o lè bẹ̀rẹ̀ nínú ilé rẹ̀
- Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òògùn ìbílẹ̀ Coronavirus tí Ooni filọ́lẹ̀? Ó ní ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn tó ní Covid-19 ló ti gbádùn
- Wo ohun táwọn ọmọ Nàìjíríà ti pàdánù lẹ́yìn tó pé ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí ìjọba ti f'òfin de Twitter
- Èmi tí wọ́n kọ́kọ́ pé ọkọ Bimbo kú gàn an ti di jálajála lórí ìròyìn burúkú náà- Jaye Kuti, ọ̀rẹ́ Bimbo Oshin
- Eèmọ̀ wọ̀lú, ẹni tó ń ta ọtí àti ògógóró gún Oníbárà rẹ̀ pa ní Osun!
- Ẹ̀yin oníṣègùn ìbílẹ̀, ẹ bá wa ṣe àwárí oògùn àjákálẹ̀ àrùn covid-19- Ìjọba Naijiria





