Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Ìdílé mi kìí ṣe Onílù rárá, ẹ̀bùn àti ìkọ́ni ni mo fi mọ̀ọ́- Adene Oluwabukola Deborah tó ń fi ìlù ṣe bẹbẹ
BBC Yoruba wa ọdọbinrin to n lu ilu bata ati gangan lọna ara kan.

Adene Oluwabukola Deborah sọ pe owo ara oun ni oun fi kọkọ ra ilu bata oun akọkọ nitori ifẹ ti oun ni si iṣẹ ilu lilu.
- Ọkùnrin mẹ́wàá ló ti fipá bá mi lòpọ̀ rí, àbúrò ìyá mi lálákọ́kọ́- Oluwatobi Raji
- Wo akọrin Highlife kan tó ń kọrin bíi Lagbaja
- Mo gbọ́ pé àwọn Yorùbá wà lára àwọn tó n gbógun ti Sunday Igboho- Ọ̀jọ̀gbọ́n Akintoye
- Iṣẹ́ àgbẹ̀ ayé àtijọ́ níra púpọ̀ ní mo ṣe ń ṣe àgbẹ̀ inú àpò
- Ẹ gba akẹ́kọ̀ọ́ láàyè láti fi èdè abínibí kọ WAEC àti JAMB - Kola Tubosun
O sọ nipa irinajo rẹ lati ibẹrẹ ko to de ibi to ti di gbajugbaja yii
Adene Deborah menuba awọn ipenija ti oju rẹ ri.

Bakan naa lo gba awọn Obi ati alagbatọ nimọran lati fi ọmọbinrin wọn sile lati se iṣẹ ti ori ran wọn.
O tun gba awọn obinrin ọdọ ni imọran lati tẹpa mọṣẹ.
- Mọ̀ nípa ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́wàá tí ò lè fi kó sí páńpẹ́ LASTMA ní Eko àti ìjìyà tó tẹ̀lẹ̀ e
- Ìtàn Ìjàpá àti ọbọ ni ìjọba àpapọ̀, àwọn agbófinró ń sọ nípa Igboho - Wole Soyinka
- Eéwo ni mo kọ́kọ́ pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo ní- Adebukola Adediran
- Akẹ́kọ̀ọ́ 32 láti Bethel Baptist School gba òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé
- Wo àwọn Fasiti Nàìjíríà tó gbégbá orókè lágbàyé