Nollywood Yoruba: Ẹjọ́ ń bẹ lọ́run fún gbogbo ẹ̀yin tí kò wàásù fáwọn tó ń tẹ lé yín lórí Instagram àti Facebook- Mike Bamiloye

Oríṣun àwòrán, Mount Zion
Gbajugbaja ajinhinrere ninu ere ori itage Kristẹni, Mike Bamiloye ti kilọ fawọn eeyan ti ko sọrọ Ọlọrun fun awọn to tẹ le wọn loju opo Facebook ati Instagram.Bamiloye ni gbogbo awọn ti ko ri nkan gidi fawọn ololufẹ wọn ju awọn nkan ti ko tọ ati nkan amunidẹṣẹ ni yoo jiyin lọjọ idajọ niwaju Eledua Oṣere naa ni ọrọ kọta dọtii ni ọpọ ilumọọka maa n bawọn ololufẹ wọn sọ lori Instagram àti Facebook.
- Àwọn alákòso BCOS tan ìmọ́lẹ̀ sí ọ̀rọ̀ iléègbé àwọn òṣíṣẹ́ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo bẹ̀rẹ̀ sí ń wó
- Màálù tí Ojo fẹ́ fi ṣègbeyàwó ló fẹ́ lọ rà tí wọ́n fi pà á, ti wọ́n gé ẹ̀yà ara rẹ̀ ní Kwara
- Kí ló ń fa rúgúdù láàrín àwọn òṣìṣẹ́ fásitì EKSU àti ìjọba Ekiti?
- Ìyálé fọ́gi mọ́ orogún rẹ̀ lórí l'Ondo, ló bá kú
- Dangote àti iléeṣẹ́ méjì ló ń ta símẹ́ntì, ìjọba gbọdọ̀ wá ńkan ṣe sí ọ̀wọ́n-gógó yìí- Aṣòfin
- Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Bamiloye sọ pe niṣe lo yẹ ki wọn maa jẹ ki awọn to n tẹ le maa pongbẹ lati gbọ ọrọ iye.Oṣere Bamiloye ni "anfaani nla ti ẹ o jiyin lọjọ idajọ ni ẹ n sọnu."O ni ko si ohun to dabi k'awọn eeyan maa fi ọrọ Ọlọrun bọ ọgọọrọ eeyan to n tẹ le wọn loju opo ayelujara Instagram ati Facebook.
Oṣere yii ti maa n sọ nipa igbe aye ododo nigba kugba loju opo ayelujara rẹ.Bamiloye ni oludasilẹ gbajugbaja ileeṣẹ oṣere Kristẹni, Mount Zion Films eleyi to ti gbe oriṣiiriṣii ere jade.
- Kí ló ń fa rúgúdù láàrín àwọn òṣìṣẹ́ fásitì EKSU àti ìjọba Ekiti?
- Wo ìpínlẹ̀ 14 ní Nàìjíríà tí America kílọ̀ pé kí àwọn eèyàn rẹ̀ má dé ...
- Màálù tí Ojo fẹ́ fi ṣègbeyàwó ló fẹ́ lọ rà tí wọ́n fi pà á, ti wọ́n gé ẹ̀yà ara rẹ̀ ní Kwara
- Ìyálé fọ́gi mọ́ orogún rẹ̀ lórí l'Ondo, ló bá kú
- Kà nípa àìsàn tó dá gbajúmọ̀ òṣèré, Kemi Afolabi wólẹ̀ tí kò fi leè ṣe sinimá
- Àwọn alákòso BCOS tan ìmọ́lẹ̀ sí ọ̀rọ̀ iléègbé àwọn òṣíṣẹ́ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo bẹ̀rẹ̀ sí ń wó

Oríṣun àwòrán, Screenshot
Àìsàn wo ló dá gbajúmọ̀ òṣèré, Kemi Afolabi wólẹ̀ tí kò fo ṣiṣẹ́ tíátà fóṣu márùn ún báyì
Gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Kẹmi Afọlabi ti sọọ di mimọ pe ojojo n ṣe ogun ara ogun oun ko le bayii ati pe idubulẹ aisan loun wa lọwọ yii.
Kẹmi Afọlabi fi to awọn ololufẹ leti lori ikanni ikansiraẹni ayelujara rẹ.
Kemi ṣalaye pe oṣu kejila, ọdun 2020 loun lọ sode iṣẹ tiata kẹyin nitori aisan naa ti ko darukọ rẹ.
Amọṣa, o dupẹ lọwọ Ọlọrun fun didasi ẹmi rẹ to si n sọ fawọn ololufẹ rẹ pe oun maa jẹri ọpẹ laipẹ.
"iṣẹ ti mo gbakẹyin ni #Disẹmb2020 niyi n ko le lọ si ode tiata kankan lọdun #2021 nitori ailera ara mi."
- Ẹlẹ́wọ̀n tó pẹ́ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n jùlọ ní Amerika gba ìtúsílẹ̀ lẹ́yìn ọdún 68 lẹ́wọ̀n
- Ṣé lóòtọ́ọ́ ni ibi ọmọ níí ṣe pẹ̀lú àyànmọ́ ọmọ láyé? Kínni pàtàkì ibi ọmọ?
- Wo àwọn 'App' tó ń ba fóònù jẹ́ ní Nàìjíríà
- Baba Ijesha kó sí gbaga ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn pé ó bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀
- Àwọn olórí orílè-èdè ilẹ̀ Áfíríkà mẹ́fà tó rọ́pò òbí wọn gẹ́gẹ́ bí ààrẹ.















