Olubadan wife Islam: Orukọ̀ olorì tuntun ti di Khadijah Moshood Lekan Balogun

Oríṣun àwòrán, @Olubadan
Ìyàwó Olúbàdàn, Olorì Joyce ti darapọ̀ mọ́ ẹ̀sìn Islam
Olori Joyce Anene to jẹ iyawo Olubadan ti ilu Ibadan, Ọba Moshood Balogun ti darapọ mọ ẹsin Islam.
Ileeṣẹ iroyin ti ijọba ipinlẹ Ọyọ, Broadcasting Corporation of Oyo state (BCOS) lo gbe iroyin naa jade.
- Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi
- Ẹ dáríjìn mí ọmọdé ló ń ṣe mí, mo kábàmọ́ ìwà tí mo wú - Akẹ́kọ̀ọ́ Chrisland Schools
- Lukman gbẹ̀yín ẹbí lọ bẹ́ orí ìkókó ti wọ́n sìn ní Abeokuta, àṣírí tú bó ṣe fẹ́ tàá
- Èsì àyẹ̀wò ohun tó ṣekú pa gbajúmọ̀ akọrin ẹ̀mí, Osinachi Nwachukwu ti jáde
- Mọ̀ síi nípa Olorì Abibat Nihinlola Adeyemi tó ti lo ọdún 60 gẹ́gẹ́ bíi olorì láàfin Alaafin Oyo
- Èèyàn bí méjì kú, ọ̀pọ̀ farapa lásìkò tí àwọn afurasí ọmọ Auxiliary àti Isota kọlu ara wọn ní Ibadan
- Emmanuel Macron borí Le Pen ní ìbò ààrẹ France
Gẹgẹ bi wọn ṣe ṣọ, Imamu agba ti ilu Ibadan, Sheikh Sheikh Abdul Ganiyy Abubakry Agbotomokekere I lo kede rẹ fun gbogbo eniyan.
Iroyin ọhun ni olori naa gba ẹsin ti ọkọ rẹ Olubadan n ṣe lo ṣe darapọ mọ ilana ẹsin musumi ni asiko ẹkọ Ramadan ti wọn n ṣe ni Yidi Agodi, ni Ibadan.
Olori ni aafin wa n jẹ orukọ tuntun gẹgẹ bi Ilana Musulumi ti wọn si pe e ni Olori Khadijah Mahood Lekan Balogun, to si ka kalimatul-shahadah ni asiko ayẹyẹ naa.
Oṣu to kọja ni wọn ya Ọba Lekan Balogun gẹgẹ bi Olubadan ti ilu Ibadan, ni ipinlẹ Ọyọ.
Lara awọn to pejọ si ibi ayẹyẹ naa ni igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo, Igbakeji aarẹ tẹlẹri ni Naijiria, Atiku Abubakar, Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi, gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ati gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiọdun.
- Adájọ́ sún ìgbẹ́jọ́ síwájú lẹ́yìn tí afurasí kan tó lọ́wọ́ nínú ikú Timothy Adegoke ṣubú nílé ẹjọ́
- Ìyànjẹ ni fún ọmọ Naijiria tí mi ò bá fẹ̀hìntì báyìí- Osinbajo
- Àwọn olùdíje sípò Ààrẹ lẹ́gbẹ́ òṣèlú PDP túká, ìmọ̀ràn wọn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
- Njẹ́ o mọ̀ pé láàrín ìṣẹ́jú méjì, ọmọdé kan ń kú nítorí àìsàn ibà??
- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ nípa ikú Baálẹ̀ àti èèyàn méjì tó kú l'Ondo táwọn ọ̀dọ́ ń so ikú wọn mọ́ agbófinró lọ́rùn
- Àjọ NDLEA nawọ́ gán ọkùnrin tó lọ́wọ́ nípa ẹ̀sùn N3bn egbògi Tramadol tí Abba Kyari ń kojú
- Okùnrin tó so àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mọ́lẹ̀ bíi ewúrẹ́, tó sì nà wọ́n rí ẹ̀wọ̀n ogún ọdún he
- 'Mo dáríji ẹni tó pa mí lọ́kọ́, mò sì gbà kí àwọn ọmọ wa fẹ́ ara wọn'
- Emmanuel Macron borí Le Pen ní ìbò ààrẹ France















